Safu ni Iya Dele at’Anti Sikira fẹẹ gbooru ara ninu ojo ni

Ọjọ keji ni mo too le ṣalaye ohun to ṣẹlẹ nile fun Safu.  Nigba ta a de…

Nwakali gba bọọlu fun kilọọbu lẹyin ọdun kan

Oluyinka Soyemi Lẹyin ọdun kan ati oṣu mẹta ti balogun ikọ agbabọọlu Golden Eaglets ilẹ Naijiria…

Ibo 1979 ku si dẹdẹ, n lawọn adigunjale ba ko girigiri ba awọn oloṣelu atijọba Ọbasanjọ (4)

Iroyin ti gbogbo ọmọ Naijiria ti n reti ni. Loootọ wọn ti gbọ oriṣiiriṣii iroyin lori…

Ajọ OYTMA gbẹsẹ le mọto ijọba ipinlẹ Ọyọ, wọn lo da gosiloo silẹ

Ọlawale Ajao, Ibadan “Bi gbogbo aye ba n ṣe bayii, a dun”. Eyi lọrọ ti ọpọ…

Ọwọ ọlọpaa ti tẹ mẹta ninu awọn adigunjale to yinbọn pa Afaa Jamiu l’Ondo

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Ọwọ ọlọpaa ti tẹ awọn afurasi mẹta kan lori Afaa kan ti wọn…

Dele ti jẹwọ fawọn ọlọpaa pe oogun owo loun fẹẹ fi pata obinrin toun mu ni Warewa ṣe

Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Ni kete tawọn ọlọpaa ba pari ifọrọwanilẹnuwo ati iwadii ti wọn n ṣe…

Awọn ọlọkada yari l’Abẹokuta, wọn ni apọju ẹgbẹ ko jẹ kawọn jere

Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Bo tilẹ jẹ pe Gomina Dapọ Abiọdun sọ pe o ṣee ṣe koun…

Rẹmi jẹwọ ni kootu, o ni koun le rowo tọju iya atiyawo oun loun ṣe n jale

Florence Babaṣọla, Osogbo Ifamoyegun Rẹmi, ẹni ọdun mejidinlogoji, ni aṣoju ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ọṣun ti taari…

Ijọba fi oṣu mẹfa kun igbele awọn alaga kansu fẹsun ṣiṣe owo ilu baṣubaṣu

Stephen Ajagbe, Ilorin Lẹyin ti oṣu mẹfa akọkọ tijọba fi jawee gbele-ẹ fawọn alaga ijọba ibilẹ…

Awọn mọlẹbi Olufalayi tawọn kan lu pa l’Ado-Ekiti n beere fun idajọ ododo

Oluyinka Soyemi, Ado-Ekiti Inu ọfọ nla lawọn mọlẹbi ọkunrin ẹni ọdun marundinlaaadọta kan, Olufalayi Ọbadare, wa…

Iru ajalu wo waa leleyi! Koronafairọọsi pa aṣofin Eko, Senetọ Bayọ Ọshinọwọ (Pẹpẹrito)

Faith Adebọla, Eko  ‘Koro wa o, koro is real, koro lo pa ẹgbọn mi o, ẹni…