Ijọba Ọyọ ja irawọ olukọ mẹfa, wọn ni wọn lọwọ ninu magomago idanwo

Ọlawale Ajao, Ibadan O kere tan, mẹfa ninu awọn olukọ ileewe girama to jẹ tijọba ipinlẹ…

Ibo gomina Ọṣun: Ile-ẹjọ to ga ju lọ yoo gbe idajọ kalẹ lọjọ Tusidee

Faith Adebọla Ile-ẹjọ to ga ju lọ nilẹ wa, Supreme Court, ti kede pe ọjọ Iṣẹgun,…

Igbẹjọ bẹrẹ lori awuyewuye eto idibo aarẹ, Peter Obi moju aara ẹ de kootu

Adewale Adeoye Ile-ẹjọ to n gbọ ẹjọ ẹsun to jẹ yọ lakooko eto idibo aarẹ nilẹ…

Mọto mọkanla atawọn nnkan olowo nla mi-in ni wọn ba lọwọ ọmọ Yahoo tọwọ tẹ n’Ibadan

Ọlawale Ajao, Ibadan Ọwọ ajọ to n gbogun ti iwa magomago ati ṣiṣe owo ilu mọkumọku,…

 Gowon gba Atiku ati Obi nimọran lori ẹjọ idibo aarẹ ti wọn pe

Faith Adebọla Olori orileede yii lasiko iṣejọba ologun, Ajagun-fẹyinti Yakubu Gowon, ti gba oludije funpo aarẹ…

Lẹyin ti Mọjeed ti ọgba ẹwọn de lo tun lọọ ji ọkada mẹrin l’Oṣogbo

Florence Babaṣọla, Oṣogbo Ọjọ gbogbo ni tole, ọjọ kan bayii ni tolohun lọrọ da fún ọmọkunrin…

Ki i ṣe ojuṣe ijọba lati pese iṣẹ faraalu o – Fẹmi Adeṣina

Faith Adebọla Oludamọran pataki si Aarẹ Muhammadu Buhari lori eto iroyin ati ikede, Ọgbẹni Fẹmi Adeṣina,…

Tọkọ-taya yii ji ara wọn gbe pamọ, wọn fẹẹ fi gbowo lọwọ mọlẹbi wọn

Faith Adebọla, Eko Bii ẹni n ṣere ori itage lọrọ naa jọ, ṣugbọn ki i ṣe…

Pasitọ fun ọmọ ijọ mẹwaa loyun lẹẹkan naa, ni wọn ba le e kuro niluu  

Faith Adebọla Pasitọ oniṣẹ-iyanu lawọn eeyan mọ ọn si, titi dasiko ta a si fi n…

Emi ni mo pa baba mi, ẹmi kan lo ni ki n lọọ la irin mọ wọn lori latoju-oorun- Ismail

Ọlawale Ajao, Ibadan Inu ọfọ ati airoju ni gbogbo mọlẹbi kan torukọ idile wọn n jẹ…

Lẹyin ti wọn pa meji ninu wọn, awọn ajinigbe tu eeyan mẹrinlelaaadọrin silẹ lọjọ kan ṣoṣo

Monisọla Saka Mẹrinlelaaadọrin, ninu eeyan tawọn agbebọn ji gbe labule Wanzamai, nijọba ibilẹ Tsafe, nipinlẹ Zamfara,…