Albert ni kiyawo mu omi ti wọn fi wẹ oku ẹgbọn ẹ ti ko ba mo si iku ẹ

Adewale Adeoye Awọn alaṣẹ ilu Atani, nijọba ibilẹ Ogbaru, nipinlẹ Anambra, ti foju Ọgbẹni Albert Eligbue,…

Ọwọ EFCC tẹ ọmọ Yahoo mẹjọ, eyi lawọn nnkan ti wọn ba lọwọ wọn

Adewale Adeoye Mẹjọ lara awọn ọmọ Yahoo kan ti wọn n ṣe gbaju-ẹ lori ẹrọ ayelujara…

Ile-ẹjọ ni kiyawo to fẹẹ kọ ọkọ ẹ sile da owo-ori to gba pada fun un

Adewale Adeoye A ki i jẹ meji laba Alade ni adajọ ile-ẹjọ Sharia kan, Onidaajọ Malam…

Ẹni kan ku, ọpọ fara pa, nibi ija ẹṣọ Amọtekun atawọn Hausa l’Atikankan

Taofeek Surdiq, Ado-Ekiti Lasiko ijaagboro to waye fun bii wakati kan aabọ gbako laarin ẹṣọ Amọtẹkun…

Ẹni kan ku, ọpọ fara pa nibi ija ẹṣọ Amọtekun atawọn Hausa l’Atikankan

Taofeek Surdiq, Ado-Ekiti Lasiko ijaagboro to waye fun bii wakati kan aabọ gbako laarin ẹṣọ Amọtẹkun…

Ẹẹmeji ni mo ti ba wọn kopa ninu ijinigbe, a ko ti i r’owo gba tẹni ta a ji fi ku sọdọ wa-Akinyẹmi

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Ẹẹmeji ni mo ti ba wọn kopa ninu ijinigbe, a ko ti i…

Tinubu ti tun tẹkọ leti lọ siluu oyinbo, eyi lohun to n lọọ ṣe

Monisọla Saka Aarẹ tuntun ti wọn ṣẹṣẹ dibo yan lorilẹ-ede Naijiria, Aṣiwaju Bọla Ahmed Tinubu, ti…

Buhari be awọn asofin, ẹ jọwọ, ẹ fọwọ sí ẹgbẹrin milionu dola ti mo fẹẹ ya

Monisọla Saka L’Ọjọruu Wẹsidee, ọjọ kẹwaa, oṣu Karun-un, ọdun yii, ni Aarẹ orilẹ-ede Naijiria, Muhammadu Buhari,…