Eeyan mẹfa ku, ọwọ tẹ mọkadinlogun, nibi ija awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun ni Dalemọ ati Alakukọ

Kazeem Aderounmu O kere tan, ọmọ ẹgbẹ okunkun mọkandinlogun lọwọ awọn agbofinro tẹ lagbegbe Alakukọ, niluu…

Ijọba lu awọn mọto to lufin irinna ni gbanjo l’Ekoo

Jide Alabi Mọto oriṣiiriṣii bii mẹtalelọgọrin (83) ni ijọba Eko lu ni gbanjo lọjọ Aje, Mọnde,…

Awọn janduku kọ lu oloye ẹgbẹ APC meji nibi ipade kan ni Lafiagi

Stephen Ajagbe, Ilorin Ọrọ di bo o lọ o yago lọna lọjọ Aje, Mọnde, ọsẹ yii,…

Nitori Aunty Ramota, ija nla bẹ silẹ laarin Iya Ereko ati oṣere mi-in, ọpẹlọpẹ Mr Latin

Kazeem Aderounmu Fidio kan lo kọkọ wa lori ikanni ẹrọ ayelujara, Instagiraamu ti Jamiu Azeez, ọkan…

Olukọ ileewe giga fi foto obinrin lu oyinbo ni jibiti niluu Ọffa

Stephen Ajagbe, Ilorin Olukọ ileewe giga College of Health Technology, niluu Ọffa, nipinlẹ Kwara, Ọpaṣhọla Abdullahi,…

Awa ara Ibarapa ni: A fẹ kijọba waa ba wa le Wakili, nitori ko fi awa araalu lọkan balẹ

Ọlawale Ajao, Ibadan Bo tilẹ jẹ pe ojoojumọ lawọn ara Ayetẹ, nijọba ibilẹ Ariwa Ibarapa, nipinlẹ…

Eeyan meje lo ku, wọn tun dan sun ọpọlọpọ ile ninu wahala Ilobu ati Ẹrin-Ọṣun

Florence Babaṣọla Lasiko ti a n koroyin yii jọ, o kere tan, eeyan meje lo ti…

Akapo ṣọọṣi Winners kowo jẹ, ladajọ ba sọ ọ sẹwọn ọdun mẹta

Ile-ẹjọ giga kan nipinlẹ Eko ti paṣẹ pe ki wọn lọọ sọ Pasitọ Afọlabi Samuel, ti…

Wahala n b ọ o, awọn Fulani darandaran to sa kuro n’Igangan ti ya wọ Ofiki

Olu-Theo Omolohun, Oke-Ogun Ilu Ofiki, nijọba ibilẹ Atisbo, nipinlẹ Ọyọ, gbalejo apapandodo laaarọ ọjọ Ẹti, Furaidee,…

Rasaki kọyawo ẹ silẹ pẹlu ọmọ mẹfa ni Ṣaki, o lo ja ju Ṣango lọ

Olu-Theo Omolohun, Oke-Ogun Ile-ẹjọ kọkọ-kọkọ kan to wa niluu Ṣaki, nipinlẹ Ọyọ, ti fopin si igbeyawo…

Awọn Fulani dumbu Dele bii ẹran n’Imẹkọ

Adefunkẹ Adebiyi,Abẹokuta Egbinrin ọtẹ lọrọ awọn Fulani ti wọn n fẹsun ipaniyan kan lasiko yii, paapaa…