Ọpẹyẹmi, ọmọ Alabi Pasuma, gbaṣẹ ologun l’Amẹrika, ṣinkin ninu Paso n dun

Jide Alabi Ninu idunnu nla ni gbajumọ olorin fuji nni, Alaaji Wasiu Alabi Pasuma, wa bayii…

Mohammed Bagega rọpo Ẹgbẹtokun gẹgẹ bii kọmiṣanna ọlọpaa ni Kwara

Stephen Ajagbe, Ilọrin Mohammed Lawal Bagega ni ileeṣẹ ọlọpaa ilẹ wa gbe wa si ipinlẹ Kwara…

NYSC banujẹ lori agunbanirọ tawọn janduku yinbọn pa

Dada Ajikanje Pẹlu ibanujẹ ni ajọ to n ṣamojuto eto isinlu awọn agunbanirọ, NYSC, fi kede…

Ijọba apapọ kede isinmi ọjọ mẹta fun ayẹyẹ ọdun

Ni bayii, ọjọ mẹta gbako ni ijọba apapọ ti kede ki awọn ọmọ Naijiria fi sinmi…

Ijọba Buhari yari, o loun ko ni i din owo ọkọ reluwee lati Eko si Ibadan ku

Jide Alabi Bo tilẹ jẹ pe ariwo ti araalu n pa lori iye ti wọn yoo…

Awọn sọja yinbọn pa okan ninu awọn ajinigbe to n yọ awọn eeyan Akoko lẹnu

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Ọrọ bẹyin yọ fawọn ikọ ajinigbe kan lọsẹ ta a wa yii pẹlu…

Nitori bawọn tọọgi ṣe n pa wọn nipakupa, awọn ara Ijokodo ti n sa kuro nile n’Ibadan

Ọlawale Ajao, Ibadan Eeyan mẹrin lawọn ọmọ iṣọta ti pa danu lagbegbe Ìjokòdó, n’Ibadan, laarin ọsẹ…

Nitori Korona, ijọba fofin de kanifa ati ipejọpọ rẹpẹtẹ l’ Ogun

Adefunkẹ Adebiyi,Abẹokuta Pẹlu bi Korona tawọn eeyan ro pe o ti lọ tẹlẹ ṣe tun ti…

Eeyan mẹfa padanu ẹmi wọn nibi ijamba ọkọ epo bẹntiroolu to gbina niluu Jẹbba

Stephen Ajagbe, Ilọrin Eeyan mẹfa lo padanu ẹmi wọn, ti ọpọlọpọ dukia ṣofo laaarọ Ọjọruu, Wẹsidee,…

 Latari eto aabo to mẹhẹ, Akeredolu fẹẹ gba awọn eeyan kun ikọ Amọtẹkun l’Ondo

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Latari ipenija eto aabo to n koju ipinlẹ naa lọwọ lọwọ, Gomina ipinlẹ…

Ẹwọn n run nimu Atofarati, ile onile lo lọọ fọ n’Ilawẹ-Ekiti

Oluyinka Soyemi, Ado-Ekiti To ba ṣe pe loootọ ni ọkunrin ẹni ọdun mẹrinlelogun kan, Bọla Atofarati,…