Awọn aṣofin gbe igbimọ dide lati fopin si wahala awọn ajagungbalẹ l’Ekoo

Faith Adebọla, Eko Ile-igbimọ aṣofin Eko ti fi aidunnu wọn han si bi wahala awọn janduku…

Olori ileegbimọ aṣofin agba ni ki Buhari yọ awọn ọga ologun nipo

Olori ile-igbimọ aṣofin agba, Ahmed Lawan, ti ke si Aarẹ Muhammadu Buhari lati yọ awọn olori ẹṣọ…

‘Nitori korona, ẹ yẹra fun ikorajọ ati orin aisun alẹ Keresi lọdun yii o’

Faith Adebọla, Eko Ijọba apapọ ti gba awọn ẹlẹsin Kristẹni nimọran pe tori arun korona, ki…

Awọn Aṣofin agba ti fọwọ si i ki Mahmud Yakub maa ṣe alaga INEC lọ

Ile-igbimọ aṣofin agba ti fọwọ si i bayii pe ki Ọjọgbọn Mahmud Yakub to jẹ alaga…

Taoreed Farounbi, Baba Alado, wọ wahala, wọn ni afẹmiṣofo ni

Olori ọja Aswani, l’Ekoo, Oloye Toareed Farounbi, ẹni tawọn eeyan tun mọ si Baba Alado, atawọn…

Orileede Nijee lọwọ ti tẹ Maina, ọkunrin to ko owo awọn oṣiṣẹ-fẹyinti je

Irọlẹ ọjọ Aje, Mọnde, ọsẹ yii, ni ọwọ awọn ọlọpaa ọtelẹmuyẹileeṣẹ EFCC pẹlu ifọwọsowọpọ awọn ọtelẹmuyẹ…

Oṣiṣẹ kootu jale, ni wọn ba wọ wọn lọ sile-ẹjọ l’Oṣogbo

Florence Babasola, Oṣogbo Igi a fẹyinti, to jẹ gbogbo ara kiki ẹgun lọrọ awọn oṣiṣẹ ile-ẹjọ…

Latọdun to n bọ lọ, gbogbo ẹni to ba fẹẹ gba nọmba ati lansẹnsi gbọdọ ni kaadi idanimọ ilẹ wa –FRSC

Ọga agba ajọ ẹṣọ oju popo nilẹ wa, (FRSC), Ọgbẹni Boboye Oyeyẹmi, ti kede pe bẹrẹ…

Makinde ṣabẹwo si Oyetọla, o ni oun mọriri ipa to ko lori ọrọ LAUTECH

Florence Babaṣọla Gomina ipinlẹ Ọyọ, Ṣeyi Makinde, ti ṣabẹwo si ojugba rẹ ni ipinlẹ Ọṣun, Alhaji…

Awọn ogoji agbẹ ti Boko Haram pa ko gba aṣẹ ki wọn too lọ sinu oko wọn – Ọmọọṣẹ Buhari

Aderounmu Kazeem Pupọ ninu awọn ọmọ orilẹ-ede yii ni inu wọn ko dun rara lori ọrọ…

Nitori awọn agbẹ onirẹsi mẹtalelogoji tawọn Boko Haram bẹ lori ni Borno, PDP sọko ọrọ si Buhari

Ẹgbẹ oṣelu PDP ti sọ pe ohun to foju han bayii ni pe eto aabo ti…