Awọn eleyii fipa ba obinrin sun l’Ogijo, wọn tun fidio rẹ

Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Ṣọla Ọlaoluwa, Ibrahim Kẹhinde ati Lukman Banjoko lẹ n wo yii, awọn pẹlu…

Dokita Amẹrika ti ni ki wọn ma sọ pe ko soogun fun korona mọ, oogun ẹ wa o jare

Obinrin oniṣegun oyinbo kan ni orilẹ-ede Amerika, Dokita Stella Emmanuel, ti sọ pe oogun wa fun…

Awọn ọmoleewe to fẹẹ ṣedanwo yoo wọle lọsẹ to n bọ

Awọn ọmọleewe to fẹẹ ṣedanwo oniwee mẹwaa jade ti jagun ajaye o: ijọba ti fun wọn…

Ko siṣẹ lọjọ Alamisi ati ọjọ Jimọ o, nitori ọdun Ileya ni

Ijọba apapọ orilẹ-ede yii ti kede pe ko ni i si iṣẹ ni Ọjọbọ, Tọsidee, ọtunla…

Ta ni yoo pari ija Buhari pẹlu Obasanjọ yii: Wọn o ma darukọ baba soju ọna reluwe kankan

“Ọjọ wo ni ija Buhari ati Ọbasanjọ yoo pari?” Bi ọpọ eeyan ṣe n beere lati…

Ẹ woju awọn adigunjale ati babalawo wọn to n daamu awọn eeyan lAbẹokuta

Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Ṣinkun lọwọ awọn ọlọpaa ipinlẹ Ogun tẹ awọn adigunjale mẹrin kan ati babalawo…

Ẹfun ree abeedi: Oyediran gun iyawo atọmọ-ọmọ ẹ pa l’Ọṣun

Florence Babaṣọla Kayeefi lọrọ naa jẹ fun gbogbo awọn eeyan ilu Iniṣa, nijọba ibilẹ Odo-Ọtin, nipinlẹ Ọṣun, nidaaji ọjọ Abamẹta, Satide, to…

Oshiomhole jẹwọ: o ni, ọja buruku ni mo ta fẹyin ara Edo ni 2016

Ni gbangba waalia, GRA, ilu Binni ni olori ẹgbẹ APC tẹlẹ, Adams Oshiomhole, ti sọrọ naa…

O ṣẹlẹ: Akpabio ti darukọ awọn aṣofin ti wọn jọ kowo jẹ o

Minisita to n ri si ọrọ agbegbe Niger Delta, Oloye Godswill Akpabio, ti darukọ awọn aṣofin…

O ma ṣe o, kọntena ja bọ le bọọsi akero lori n’Ilasamaja, eeyan meji lo ku lẹsẹkẹsẹ

Faith Adebọla, Eko Iku oro, iku gbigbona, gbaa ni iku to mu ẹmi eeyan meji lọ…

Ijọba ti fi katakata yanju iyooku ile to wo l’Ebute-Mẹtta, wọn ni ki lanlọọdu ile naa yọju kia

Faith Adebọla, Eko Laika ti pe ayẹwo ṣi n lọ lori ohun to fa iṣẹlẹ ile…