Meji to ku ninu awọn Fulani to n jale ni marosẹ Eko s’Ibadan ti bọ sọwọ ọlọpaa

Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Ọwọ ọlọpaa ipinlẹ Ogun ti tẹ  meji yooku ninu awọn ọmọde ole to…

Awọn ọmọ iya meji ti wọn fẹẹ ṣ’oogun owo n’Ijẹbu ti pa iya arugbo o

Ni Ijẹbu Muṣin lo ti ṣẹlẹ. Awọn ọmọ iya kan naa, Akinọla Akeem ati Muyiwa Akeem…

Awọn Hausa atawọn ọmọọta n ja l’Oṣogbo o

Ija kan teeyan ko ti i gbọ hulẹhulẹ ohun to fa a gan-an bẹ silẹ laarin…

Baba Gomina Kwara, AbdulGaniyu Abdul-Razaq, jade laye lẹni ọdun mẹtalelaaadọrun-un

Stephen Ajagbe, Ilọrin Laaarọ ọjọ Abamẹta, Satidee, yii, ni ẹbi Abdulrazaq kede iku baba Gomina Kwara,…

Bi iya yii ṣe maa n ju’di ẹ to ba n rin lọ lo jẹ ki n fipa ba a sun

Ki i ṣe awọn ọmọge nikan ni wọn gbọdọ maa ṣọra lati wọ aṣọ ti yoo…

Ileya: Ijọba Kwara fagi le ipejọpọ Yidi, ṣiṣi ile itaja atawọn ibudo igbafẹ lasiko ọdun

Stephen Ajagbe, Ilọrin Lati dẹkun atankalẹ arun Koronafairọọsi nipinlẹ Kwara, ijọba ti fagi le ipejọpọ ni…

Awọn eeyan ha sinu ile alaja mẹta to wo l’Ebute-Mẹta, l’Ekoo

 Faith Adebọla, Eko Titi di ba a ṣe n sọ yii, ariwo ẹkun ati igbe awọn…

Olori awọn aṣofin tẹlẹ, Yakubu Dogara, ti tun kuro ninu PDP, o ti pada si APC

Ni ọjọ Ẹti, Furaidee, ọsẹ yii, ni olori ileegbimọ aṣoju-ṣofin tẹle, Yakubu Dogara, kuro ninu ẹgbẹ…

Adojutẹlẹgan, ọkan ninu awọn oludije, fẹhonu han lori bi Akeredolu ṣe bori ibo abẹle l’Ondo

Olusẹyẹ Iyiade, Akurẹ. Ọkan ninu awọn oludije ibo abẹle ẹgbẹ APC to waye lọsẹ to kọja,…

Ipinlẹ Ogun ni Mumini ti ji owo lanledi rẹ, Oṣogbo lọwọ awọn Amọtẹkun ti tẹ ẹ 

Florence Babaṣọla, Oṣogbo Ọwọ awọn ikọ Amọtẹkun ipinlẹ Ọṣun ti tẹ ọmọkunrin kan, Mumini Saheed, ẹni…

O ma ṣe o: Baba Onipuulu yii si binu para ẹ ni Saabo, Eko

Ọkunrin oniṣọọbu puulu (pool) kan, nibi tawọn eeyan ti n ta tẹtẹ ati baba-ijẹbu ninu ọja…