Ibo abẹle Ondo:Ajayi ki Jẹgẹdẹ ku oriire, o loun tí gba f’Ọlọrun

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ  Igbakeji gomina ipinlẹ Ondo, Ọnarebu Agboọla Ajayi, ti ki Eyitayọ Jẹgẹdẹ ku oriire…

IBO AWỌN PDP L’ONDO: JẸGẸDẸ WỌLE, AGBOỌLA JA BỌ!

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Pẹlu gbogbo ilakaka Igbakeji Gomina Ipinlẹ Ondo, Ajayi Agboọla, lati koju  ọga rẹ,…

Nitori Korona, Awujalẹ fagi le Ojude Ọba t’ọdun yii

Nitori arun aṣekupani Koronafairọọsi to gbode kan, Awujalẹ ilẹ Ijẹbu, Ọba Sikiru Adetọna ti kede pe…

O ma wa ga o, wọn tun pa ọmọ ọdun mẹrindinlogun mi-in l’Akinyẹle, n’Ibadan

Ọlawale Ajao, Ibadan Niṣe ni gbogbo eeyan ro pe iku ojiji tawọn olubi ẹda kan fi…

Ija de: Alaafin lo nilẹ ni, abi awọn ẹgbẹ ọmọlẹyin Kristi?

Ni bayii, o da bii pe ẹgbẹ awọn Kristẹni ti wọn n pe ni CAN (Christian…

O ma ṣe o, terela Dangote tun pa baba atọmọ ẹ ni Lọkọja

Ọrọ terela Dangote to paayan ni ipinẹ Ogun ni lọsẹ to kọja lawọn eeyan ṣii n…

Buhari yari, o ni, ‘E ma ba mi le awọn eeyan mi lọ!’

Aarẹ orilẹ-ede yiii, Ọgagun agba Muhammadu Buhari ti yari mọ awọn aṣofin Naijiria lọwọ bayii o,…

Iru ki waa leleyii, ọmọkunrin yii si para ẹ niwaju iya ẹ ni Surulere

Faith Adebọla  Bi ọkunrin ẹni ọdun mejilelọgbọn kan, Aboh Ogbeche, ṣe jokoo siwaju mama ẹ ni…

Laaarọ yii, Buhari pade Jonathan ninu Aso Rock

Olori ijọba Naijiria, Aarẹ Muhammadu Buhari, ṣe akanṣe ipade kan loni-in yii pẹlu aarẹ ilẹ wa…

Ija n bọ: Awọn aṣofin ti ni kawọn olori ologun gbogbo fipo silẹ o

Ile-gbimọ aṣofin agba ilẹ yii ti paṣẹ loni-in yii pe ki awọn olori ologun gbogbo fi…

Awọn aṣofin beere boya o kowo jẹ ni o, n lọga ileeṣẹ NDDC ba daku

  Ọrọ buruku ni, koda o mu ẹrin lọwọ, ṣugbọn awọn ti wọn wa nibẹ ko…