Ife-ẹyẹ agbaye: Morocco wọ ipele to kangun si aṣekagba fungba akọkọ

Faith Adebọla Sinkin bii ẹni jẹ tẹte oriire lawọn ọmọ orileede Morocco atawọn ololufẹ bọọlu afẹsẹgba…

Super Eagles ko ti i yege fun AFCON 2022

Oluyinka Soyemi Lalẹ ọjọ Iṣẹgun, Tusidee, ọsẹ yii, ni ẹgbẹ agbabọọlu Super Eagles ilẹ wa iba…

Champions League: Eyi lawọn kilọọbu ti yoo figagbaga

Idije UEFA Champions League yoo bẹrẹ logunjọ, oṣu yii, awọn alaṣẹ si ti ṣeto ipin mẹjọ…

Israel Adesanya, ọmọ Naijiria to n ja ijakadi fagba han wọn ni Abu Dhabi

Ọmọ ilẹ wa to n ja lagbo ijakadi Ultimate fighting Championship (UFC), Israel Adesanya, ti fitan…

Efe Ajagba gba ife-ẹyẹ kẹrinla lagbo ẹṣẹ kikan

Oluyinka Soyemi Ọmọ ilẹ wa to n ṣe bẹbẹ lagbo ẹṣẹ kikan lagbaaye, Efe Ajagba, ti…

Umar Sadiq dero ileewosan lẹyin ija ni Russia

Oluyinka Soyemi Abẹṣẹ-ku-bii-ojo ọmọ ilẹ wa, Umar Sadiq, ti n gba itọju nileeowsan bayii lẹyin ija…

Ife-ẹyẹ idije Afrika poora ni Egypt

Oluyinka Soyemi Ife-ẹyẹ ilẹ Afrika to wa lọwọ Egypt ti poora kuro ni olu-ile ajọ ere…

Ẹ fi papa iṣere Ilọrin sọri Rashidi Yẹkini- Pinnick

Stephen Ajagbe, Ilọrin Lọna ati bu ọla fun ogbontarigi agbabọọlu ilẹ wa to ti doloogbe, Rashidi…

Ideye darapọ mọ Goztepe ilẹ Turkey

Oluyinka Soyemi Agbabọọlu ilẹ Naijiria, Brown Ideye, ti darapọ mọ ẹgbẹ agbabọọlu Goztepe ilẹ Turkey. Gẹgẹ…

Bayern lu Barca laluwo pẹlu ami-ayo mẹjọ si meji

Iya ami-ayo mẹjọ si meji ki i ṣe nnkan ti ẹgbẹ agbabọọlu Barcelona ilẹ Spain ro…

Willian balẹ si Arsenal lẹyin ọdun meje ni Chelsea

Oluyinka Soyemi Agbabọọlu Chelsea tẹlẹ, Willian Borges da Silva, ti balẹ si Arsenal lẹyin to tọwọ…