Ọlawale Ajao, Ibadan Ẹgbẹ oṣelu All Progresives Congress (APC), ipinlẹ Ọyọ ti n ṣeto labẹnu lati fa ọkan ninu awọn to n dije dupo gomina lorukọ ẹgbẹ wọn kalẹ nibi idibo abẹlẹ ẹgbẹ ọhun ti yoo waye l’Ọjọbọ, Tọsidee, ọsẹ yii. Agba oṣelu ẹgbẹ naa, Sẹnetọ Ayọ Ademọla Adeṣeun, lo …
Read More »Ọwọ ọlọpaa tẹ awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun ti wọn ji oyinbo gbe l’Ekiti
Taofeek Surdiq, Ado-Ekiti Ọwọ palaba awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun ti wọn fọ banki Igbalode kan ni Iyin-Ekiti t segi, pẹlu bi ọwọ ajọ Ọlọpa ipinlẹ naa ṣe tẹ wọn. Gẹgẹ bii alukoro ajọ ọlọpa ipinlẹ Ekiti Ọgbẹni Sunday Abutu, ṣe sọ, oni awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun naa ti ọwọ wọn …
Read More »Emir Katisina sọ fun Ọṣinbajo: Gbọn-in gbọn-in la wa lẹyin rẹ lati di aarẹ Naijiria
Monisọla Saka Ẹmia ilu Katsina, Abdulmumin Usman, sọ pe Igbakeji Aarẹ ilẹ wa, Yẹmi Ọṣinbajo, ti ni gbogbo iriri teeyan nilo lati tukọ Naijiria gẹgẹ bii aarẹ. Ọba alaye naa sọ eyi lasiko to gbalejo Igbakeji Aarẹ naa to ṣabẹwo si i laafin rẹ lọjọ Abamẹta, Satide, ọjọ kọkanlelogun, oṣu …
Read More »Ọmọọdun mẹtala ti Ayọbami n ṣe lẹsinni fun lo fipa ṣe ‘kinni’ fun l’Agọ-Iwoye
Gbenga Amos, Abeokuta Afaimọ ki ọkunrin ẹni ọdun mẹẹẹdọgbọn yii, Ayọbami Oluwatobilọba Runsewe, ma ti maa ge’ka abamọ jẹ lori ẹsun ti wọn fi kan an, ṣugbọn abamọ ki i ṣaaju ọrọ, majeṣin ọmọọdun mẹtala pere ti wọn ni ko maa kọ ni lẹsinni lo ki mọlẹ, o si fipa …
Read More »Lanlọọdu ati getimaanu pa ọmọọdun mẹrin, wọn yọ ẹya ara ẹ lati fi ṣoogun owo
Faith Adebọla Diẹ lo ku kawọn araalu tinu n bi dana sun baba getimaanu kan nigba ti aṣiri oun ati ọga rẹ, Ọgbẹni Emmanuel, tu pe awọn ni wọn ṣeku pa ọmọkunrin ọmọọdun mẹrin kan, ti wọn si yọ ẹya ara ẹ lati fi ṣoogun owo. Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ …
Read More »Nitori ti wọn dari alaisan lọ si ọsibitu aladaani, ijọba da dokita ati nọọsi duro nipinlẹ Ọyọ
Ọlawale Ajao, Ibadan Nitori ti wọn dari awọn alaisan lọ sileewosan aladaani, ijọba ipinlẹ Ọyọ ti da dokita kan ati nọọsi kan duro. Alaga igbimọ to n mojuto eto ilera nipinlẹ naa, Dokita Gbọla Adetunji, lo kede igbesẹ naa nibi atẹjade kan to fi ṣọwọ sawọn oniroyin lọjọ Abamẹta, Satide, …
Read More »Nibi ti Ṣẹgun atawọn ọrẹ ẹ ti n ṣepade oko ole ti wọn fẹẹ lọ lawọn ọlọpaa ka wọn mọ
Gbenga Amos, Abẹokuta Ṣẹgun Azeez, afurasi adigunjale ẹni ọdun mẹrindinlọgbọn, tọwọ awọn ọlọpaa ẹka ileeṣẹ wọn ni Sango Ọta, ipinlẹ Ogun, ba, ti jẹwọ pe ipade bawọn ṣe fẹẹ ṣaṣeyọri nibi idigunjale ti awọn n gbero lati lọ lawọn n ṣe lọwọ tawọn ọlọpaa fi ka awọn mọ. Bi Alukoro …
Read More »Ileelẹ ti wọn fẹẹ sọ di alaja mẹta wo l’Ekoo, oku mẹrin ni wọn hu jade
Ileelẹ ti wọn fẹẹ sọ di alaja mẹta wo l’Ekoo, oku mẹrin ni wọn hu jade Faith Adebọla, Eko Titi dasiko yii, oku eeyan mẹrin ni wọn ti hu jade labẹ awoku ile alaja mẹta kan ti wọn n kọ lọwọ, lasiko ti ile naa rọ lulẹ lọjọ Abamẹta, Satide, …
Read More »Awọn ọdọ tun dana sunle, ṣọọbu ni Bauchi, wọn lọmọbinrin kan sọrọ odi si Islam
Ọrẹoluwa Adedeji Wahala mi-in tun ṣẹlẹ ni ilu kan ti wọn n pe ni Katangan-Waji, ni agbegbe ijọba ibilẹ Warji, nipinlẹ Bauchi, lọjọ Ẹti, Furaidee, opin ọsẹ yii. Ọmọbinrin kan ni wọn fẹsun kan pe o sọrọ odi si Anọbi nigba to n sọrọ nipa Deborah Samuel ti wọn pa …
Read More »Arẹmu Afọlayan ṣepe nla fawọn oloṣelu, o lawọn lo ba Naijiria jẹ
Faith Adebọla Gbajugbaja oṣere tiata ilẹ wa kan, Arẹmu Afọlayan, ti wọn epe nla fawọn oloṣelu latori Aarẹ ilẹ wa, o lawọn ni wọn mu ipọnju ba Naijiria, awọn si ni wọn ko jẹ ki orileede naa goke agba bo ṣe yẹ. Ninu fidio kan to gbe sori opo ayelujara …
Read More »Ijọba gbọdọ gba awọn ọlọpaa si i ti a ba fẹ ki wahala eto aabo dopin lorileede yii – Ọsinbajo
Florence Babaṣọla, Oṣogbo Igbakeji Aarẹ orileede yii, Ọjọgbọn Yẹmi Ọsinbajo, ti sọ pe ọkan pataki lara awọn ipenija to n koju orileede yii bayii ni aisi eto aabo to peye, o si ṣee ṣe lati koju ti ijọba ba le gba awọn ọlọpaa si i. Yatọ si eyi, Ọsinbajo dabaa …
Read More »