Ijọba Kwara pe ipade apero lati gbogun ti lilo egboogi oloro

Ibrahim Alagunmu, Ilọrin Gomina ipinlẹ Kwara, Abdulraman Abdulrasaq, lo ṣide ipade pataki kan, nibi ti wọn…

Adiẹ ti jẹ’fun ara wọn o: Umar pa Fulani ẹgbẹ ẹ l’Akoko, o lo n gbero lati ji oun gbe

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Ọmọkunrin ẹni ogun ọdun kan, Umar Ibrahim, lo ti wa nikaawọ ileeṣẹ ọlọpaa…

Oluwoo gba Tinubu nimọran: Ẹ ṣi bọda, ki ẹ si gbẹsẹ  lori fifofin de kiko ounjẹ wọle

Florence Babaṣọla, Oṣogbo Latari wahala ọwọngogo ounjẹ to n mu awọn eeyan orileede Naijiria fojoojumọ pariwo,…

Ọwọ tẹ Ayọmide l’Oṣogbo o, waya ile onile lo lọọ ji tu

Florence Babaṣọla, Oṣogbo Ayọmide David Popoọla, ẹni ọdun mejilelọgbọn, lọwọ awọn ọlọpaa ti tẹ niluu Oṣogbo…

Ẹwọn ọdun mẹwaa ni wọn ju ‘Mama Boko Haram’ si

Monisọla Saka Aisha Alkali Wakil, ti wọn maa n pe ni Mama Boko Haram, atawọn ọkunrin…

Ina sọ nile-ẹjọ giga ipinlẹ Kwara, ọpọ dukia jona gburugburu

Ibrahim Alagunmu, Ilọrin L’ọjọ Iṣẹgun, Tusidee, ọjọ kẹtala, oṣu Keji yii, ni ina sọ nile-ẹjọ giga…

Damilare fo fẹnsi lọọ ji jẹnẹretọ nla l’Abẹokuta, ni wọn ba ka a mọ

Faith Adebọla Afaimọ ni ọkunrin ti wọn pe ni Damilare yii ko ni i di ẹni…

Lati kapa awọn agbebọn: Eyi lohun ti Tinubu fẹẹ ṣe

Faith Adebọla Iṣakoso Aarẹ Bọla Ahmed Tinubu ti ni kawọn araalu lọọ fọkan balẹ lori ipenija…

Ọlọpaa ti mu awọn gende mẹrin to maa n ja foonu gba l’Ekoo

Adewale Adeoye Mẹrin lara awọn janduku atawọn alọnilọwọ-gba to n da alaafia ipinlẹ Eko laamu nigba gbogbo lọwọ awọn…

Nitori ọrọ ti ko to nnkan, iyaale ile yii fọbẹ gun ọrẹ rẹ pa

Adewale Adeoye Ọdọ awọn alaṣẹ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko niyaale ile kan, Abilekọ Cynthia Aigbondon, to fọbẹ aṣooro  gun ọrẹ rẹ, Oloogbe Basirat Adio, pa lọjọ Aiku, Sannde, ọjọ kọkanla, oṣu Keji, ọdun yii…

Ọwọ tẹ Ayọmide l’Oṣogbo, waya ile onile lo lọọ ji tu

Florence Babaṣọla, Oṣogbo Ayọmide David Popoọla, ẹni ọdun mejilelọgbọn, lọwọ awọn ọlọpaa ti tẹ niluu Oṣogbo…