Ọlawale Ajao, Ibadan Nitori bi wọn ṣe fẹẹ yọ ọ nipo, Igbakeji gomina ipinlẹ Ọyọ, Ẹnjinnia Rauf Ọlaniyan, kọ lati yọju si ileegbimọ aṣofin nigba ti awọn aṣofin ipinlẹ naa ranṣẹ pe e. Tẹ o ba gbagbe, lati nnkan bii ọsẹ meji sẹyin ti Ẹnjinnia Ọlaniyan ti fi ẹgbẹ oṣelu …
Read More »Agbẹjọro lọ si kootu pẹlu aṣọ ẹsin abalaye, o ni idajọ ile-ẹjọ to ga ju lọ loun tẹle
Jọkẹ Amọri Pẹlu iyanu lawọn eeyan fi n wo ọkunrin agbẹjọro ajafẹtọọ ọmọniyan kan, Malcom Omoirhobo, to lọ sile-ẹjọ giga to ga ju lọ niluu Abuja pẹlu aṣọ ẹsin abalaye l’Ọjọbọ, Tọsidee, ọsẹ yii. Ọkunrin to wọ ṣokoto pupa lori ẹwu funfun, to waa wọ aṣọ awọn agbẹjọro le e …
Read More »Ọwọ wa ti tẹ awọn afurasi kan lori akọlu to waye ni ṣọọsi Ọwọ-Adelẹyẹ
Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Awọn afurasi kan to ṣee ṣe ki wọn mọ nipa iṣẹlẹ akọlu to waye ninu sọọsi Katoliiki Francis Mimọ tilu Ọwọ lọjọ Aiku, Sannde, ọjọ karun-un, oṣu Kẹfa yii, lọwọ ti tẹ, ti wọn si ti wa nikaawọ ẹṣọ Amọtẹkun ipinlẹ Ondo lọwọlọwọ. Alakooso ẹṣọ Amọtẹkun nipinlẹ …
Read More »Nitori to n jade pẹlu ọrẹkunrin mi-in, Fatai atawọn ọrẹ ẹ lu ọrẹbinrin rẹ lalubami ni Kwara
Ibrahim Alagunmu, Ilọrin Akolo ileeṣẹ ọlọpaa ni ọdọmọkunrin kan, Fatai, wa bayii. Niṣe lo gbimọ-pọ pẹlu awọn ọrẹ ẹ, wọn bọ ọrẹbinrin rẹ, Adukẹ, sihooho, wọn si lu u bii bẹmbẹ nitori ẹsun pe o n fẹ ọkunrin miiran. Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Kwara, SP Ajayi Okasanmi, sọ pe ọwọ …
Read More »Pẹlu bawọn ọlọpaa ṣe n wa a, Portable olorin ṣegbeyawo pẹlu iya ọmọ ẹ
Monisọla Saka Idunnu nla lo ṣubu lu ayọ fun gbajugbaja olorin asiko to kọ orin Zaa zuh nni, Habeebullah Okikiọla, ti wọn n pe ni Portable. Pẹlu bi awọn ọlọpaa ṣe ni awọn n wa ọmọkunrin naa, eyi ko di i lọwọ lati ṣe igbeyawo pẹlu obinrin to bimọ fun …
Read More »Wọn fofin de akẹkọọ ileewe imọ ofin to gbe ike omi sẹnu
Monisọla Saka Ile ẹkọ imọ ofin ilẹ wa (Nigerian Law school), ẹka ti ipinlẹ Eko, ti bẹrẹ iwadii lori akẹkọọ kan ti wọn lo dori ike kọ ọna ọfun rẹ, to fi mu omi lasiko ti wọn n jẹun alẹ (dinner) ile ẹkọ naa lọwọ. Wọn ni igbesẹ naa lodi …
Read More »Lẹyin oṣu marun-un ti Jimoh atawọn ẹmẹwa rẹ ja ọkada gba l’Akurẹ lọwọ tẹ wọn
Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Awọn afurasi ole a-ji-ọkada meji lọwọ palaba wọn ṣegi, awọn agbofinro lo mu wọn lagbegbe Ẹyin-Ala, nijọba ibilẹ Guusu Akurẹ, lọsẹ to kọja yii. Gẹgẹ ba a ṣe gbọ, awọn afurasi mejeeji, Jimọh Dele ati Uwanfor Destiny, lọwọ pada tẹ lẹyin bii oṣu marun-un gbako ti wọn …
Read More »Lẹyin tawọn meje ti lọ, sẹnetọ mejidinlogun tun fẹẹ binu kuro lẹgbẹ oṣelu APC
Faith Adebọla Ko din ni wakati meji gbako ti Alaga apapọ ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress (APC), Sẹnetọ Abdullahi Adamu fi tilẹkun mọri ṣepade aṣelaagun pẹlu awọn sẹnetọ ti wọn jẹ ọmọ ẹgbẹ oṣelu naa nileegbimọ aṣofin agba, l’Abuja, l’Ọjọruu, Wẹsidee, ọjọ kejidinlogun, oṣu Kẹfa yii. Eyi ko ṣẹyin bi …
Read More »Lẹyin ti Tosin digun ja tọkọ-taya lole tan lo tun fẹẹ fipa ba iyawo lo pọ n’Idanre
Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Ogbologboo adigunjale kan, Tosin Ọmọniyi lọwọ awọn ọlọpaa tẹ niluu Idanre loru ọjọ Aje, Mọnde, ọsẹ to kọja, nibi to ti n gbiyanju ati fipa ba abilekọ kan ta a forukọ bo laṣiiri sun lẹyin to ti kọkọ ja tọkọ-taya ọhun lole owo nla. Tosin ni wọn …
Read More »Oyebanji, igbakeji rẹ gba iwe-ẹri mo yege Taofeek Surdiq, Ado-Ekiti Gomina ti wọn ṣẹṣẹ dibo yan nipinlẹ Ekiti, Ọgbẹni Biọdun Oyebanji ati Igbakeji rẹ, Arabinrin Monisade Afuyẹ, ti gba iwe-ẹri mo yege lati ọwọ ajọ eleto idibo, eyi to n tọka si aṣeyege wọn ninu eto idibo gomina to waye …
Read More »Rasaq ja ero to gbe lole, o tun fiba ba a lo pọ n’Ifọ
Gbenga Amos, Abẹokuta Afaimọ ni gende ẹni ọdun mejilelogun to n wa Marwa, Rasaq Taoheed, ko ni i fẹwọn ọlọjọ gbọọrọ jura lori ẹsun ti wọn fi kan an pe ṣe lo yọ ibọn si ero to gbe lọjọ Aje, Mọnde, ọsẹ yii. Lẹyin to ja a lole owo tan …
Read More »