Wọn gbọdọ yanju ẹjọ to ṣu yọ lẹyin idibo ki wọn too gbejọba silẹ – Agbakoba

Monisọla Saka Olori ẹgbẹ awọn amofin nilẹ Naijiria tẹlẹ, Olisa Agbakoba, ti gba ileeṣẹ eto idajọ…

Eyi lohun ti Portable tun ṣe fawọn ọlọpaa

Jọkẹ Amọri Owe tawọn Yoruba maa n pa ni pe ‘a ki i ti kootu bọ…

O ma ṣe o, ọdẹ adugbo pokunso l’Ado-Ekiti, ṣugbọn ọlọpaa ni wọn pa a ni

Taofeek Surdiq, Ado-Ekiti Kayeefi nla ni iku ọkunrin ẹni aadọta ọdun (50), kan jẹ fun gbogbo…

Kayeefi! Nitori owo ti wọn fẹẹ fun un, ọdọmọbinrin yii ba aja rẹ lo pọ

Adewale Adeoye Ni bayii, awọn ọlọpaa ilu Mississippi, lorilẹ-ede Amẹrika ti sọ pe iwadii ti bẹrẹ…

Ẹwa Ruth lo wọ mi loju ti mo fi fipa ba a laṣepọ, kaṣiiri ma baa tu ni mo ṣe pa a-Friday

 Adeoye Adewale Awọn iṣẹlẹ to n ṣẹlẹ laye ode oni buru jai, to maa n ṣoro…

Inu oko lawọn ọdọ kan ti n ṣiṣẹ tawọn agbebọn fi ko ọgọrin lọ ninu wọn

Adeoye Adewale Titi di akoko ta a n ko iroyin yii jọ, awọn janduku agbebọn ti…

Ijamba ina fọkẹ aimọye dukia ṣofo n’Ilọrin 

Ibrahim Alagunmu, Ilọrin Titi digba ti a n ko iroyin yii jọ, ko sẹni to mọ…

Pasitọ ṣe gbaju-ẹ fawọn to waa ṣe isọji fun, owo ati ọpọlọpọ foonu wọn lo ko lọ n’Ibadan

Ọlawale Ajao, Ibadan Gẹgẹ bii ọrọ inu Bibeli to sọ pe nigba ti aye ba n…

Lẹyin to yi orukọ ẹ pada si ti Musulumi, Mercy Aigbe n mura Mecca

Monisọla Saka Bi gbogbo nnkan ba lọ bi oṣere-binrin ilẹ wa nni, Mercy Aigbe, to ti…

Eyi ni bawọn ọlọkada ṣe pa ọlọpaa kan nipa oro l’Ekoo

Ismail Adeẹyọ ati Faith Adebọla L’Ọjọruu, Wẹsidee, ọjọ karun-un, oṣu Kẹrin, ọdun yii, ni ọlọpaa kan pade iku ojiji nibi…

O ṣẹlẹ, adajọ ni ki wọn lọọ pa adiẹ to n fariwo daamu awọn araadugbo

Monisọla Saka Ọrọ buruku toun tẹrin lọrọ idajọ kan to waye ni kootu Majisireeti kan niluu…