Faith Adebọla “Olori to ni iriiri ni Naijiria nilo lasiko ti nnkan le koko yii. Ọdun meje ti mo ti lo nipo igbakeji aarẹ ti fun mi ni iriri lẹnu iṣejọba, emi ni mo kunju oṣuwọn ju lọ lati pese idari to maa tun nnkan ṣe daadaa.” Ọrọ yii lo …
Read More »Idi ti Jonathan ko fi le dupo aarẹ lọdun 2023- Falana
Monisọla Saka Idi ti Jonathan ko fi le dupo aarẹ lọdun 2023- Falana Agbẹjọro to tun jẹ ajafẹtọọ ọmọniyan nipinlẹ Eko, Ọgbẹni Fẹmi Falana, ti sọ l’Ọjọbọ, Tọsidee, ọsẹ yii, pe aarẹ ilẹ wa tẹlẹ, Goodluck Ebele Jonathan, ko le jade dupo aarẹ to n bọ lọna lọdun 2023, nitori …
Read More »Iyatọ yoo ba eto ọrọ-aje ipinlẹ Ọṣun ti mo ba di gomina – Akin Ogunbiyi
Florence Babaṣọla, Oṣogbo Oludije funpo gomina ipinlẹ Ọṣun labẹ asia ẹgbẹ oṣelu Accord Party, Dokita Akin Ogunbiyi, ti sọ pe gbogbo iriri ati ọgbọn inu to sọ oun di oludaṣẹsilẹ ti ko ṣee fọwọ rọ sẹyin lorileede yii loun yoo lo lati ri i pe ipinlẹ Ọṣun di apewaawo si …
Read More »Awọn afiniṣowo pa agunbanirọ niluu Abuja, wọn yọ gbogbo ẹya ara rẹ lọ
Monisọla Saka Ofo nla gbaa leyi jẹ, ọmọbinrin agunbanirọ to sọnu, Stephanie Ṣe-Ember Terungwa, pẹlu nọmba idanimọ FC/21B/5807, ni wọn ti pada ri, ṣugbọn wọn ko ri i laaye, oku rẹ ni wọn ri, bẹẹ ni ẹya ara rẹ ko pe mọ, wọn ti yọ oju ara rẹ atawọn nnkan …
Read More »O ma ṣe o, ọkunrin kan padanu ẹmi rẹ lasiko to fẹẹ yọ foonu rẹ to ja bọ sinu ṣalanga
Monisọla Saka Ọkunrin ẹni ogoji ọdun kan, Mu’azu Garba, ti ku sinu sọkawee ni Jigirya, nijọba ibilẹ Nassarawa, nipinlẹ Kano, lakooko to n gbiyanju lati yọ foonu rẹ to ja bọ nigba to n yagbẹ lọwọ. Alukoro ileeṣẹ panapana nipinlẹ naa, Alhaji Saminu Abdullahi, lo fọrọ ọhun lede l’Ọjọbọ, Tọsidee, …
Read More »Itunu Aawẹ: Ijọba kede ọjọ Aje ati Iṣẹgun gẹgẹ bii isinmi lẹnu iṣẹ
Faith Adebọla Ijọba apapọ ilẹ wa ti kede lọjọ Aje, Mọnde, ọjọ keji, oṣu Karun-un, ati ọjọ Iṣẹgun, Tusidee, ọjọ kẹta, oṣu Keji, ọdun yii, gẹgẹ bii ọjọ isinmi lẹnu iṣẹ. Ọlude naa waye latari ayẹyẹ ayajọ awọn oṣiṣẹ to bọ si ọjọ Aiku, Sannde, ọjọ kin-in-ni, oṣu Karun-un, ọdun …
Read More »Lẹyin ti Victor atawọn ọrẹ ẹ fipa ba ọrẹbinrin ẹ lo pọ tan ni wọn ju fọto ẹ sori ẹrọ ayeujara l’Ekiti
Taofeek Surdiq, Ado-Ekiti Eka to n gbogun ti fifi ipa ba ọmọ kekere lajọṣepọ (Juvenile Welfare Centre), ti ileeṣẹ ọlọpaa Ekiti, ti kede pe ọwọ awọn ti tẹ ọdọ langba mẹrin pẹlu ẹsun pe wọn fipa ba ọmọdebinrin ẹni ọdun mejidinlọgbọn kan lo pọ ni Ado-Ekiti. Gẹgẹ bii Alukoro ileeṣẹ …
Read More »Awọn agbebọn ji olori abule kan gbe, wọn ni kaadi ipe, tiramadọọlu, siga ati epo bẹtiroolu lawọn fẹ
Monisọla Saka Awọn Agbebọn ti ji Ọgbẹni Ayuba Dodo Dakolo to jẹ Baalẹ abule Rajina to wa nijọba ibilẹ Kachia, n’ipinlẹ Kaduna, gbe. Baba yii ni wọn ji gbe pẹlu awọn agbẹ mi-in ni agbegbe Kurmi, nitosi Chikwale, nijọba ibilẹ kan naa. Abule Rijana to jẹ ilu kan to wa …
Read More »Pasitọ Abraham ni aye ti fẹẹ parẹ, o ni kawọn ọmọ ijọ dawo foun ki wọn le rọrun wọ l’Omuo-Ekiti
Taofeek Surdiq, Ado-Ekiti Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ekiti ti tẹ Pasitọ ijọ Christ High Commission Ministry, ti gbogbo eeyan tun mọ si Royal Christ Assembly, to wa ni Kaduna, Nuah Abraham. Ẹsun ti wọn fi kan pasitọ yii ni pe o ko awọn ọmọ ijọ rẹ wa lati ipinlẹ Kaduna si …
Read More »Arẹgbẹṣọla, Amosun lo mu mi de ọdọ Buhari
Ọrẹoluwa Adedeji Yatọ si ohun ti awọn kan n sọ kiri pe Aṣiwaju Tinubu lo fa Igbakeji Aarẹ, Yẹmi Ọṣinbajo, le Buhari lọwọ fun ipo naa lọdun 2015, ọkunrin naa ti sọ pe ọrọ ko ri bẹẹ o. O ni Gomina ipinlẹ Ọṣun tẹlẹ, Raufu Arẹgbẹṣọla, ati ojugba rẹ to …
Read More »Lati Sagamu ni Afeez ti lọọ yọ eyin oku to fẹẹ fi ṣoogun owo ni itẹkuu kan n’Ileṣa
Florence Babaṣọla, Oṣogbo Lasiko ti ọmọkunrin ẹni ọdun mẹtalelọgbọn kan, Afeez Odusanya, n yọ eyin oku to fẹẹ fi ṣoogun owo lọwọ ẹṣọ Amọtẹkun ipinlẹ Ọṣun tẹ ẹ. Afeez, mẹkaniiki ọkọ akoyọyọ (Truck), ni wọn ka eyin mejila pẹlu eegun-ika ọwọ meji mọ lọwọ. Alakooso Amọtẹkun nipinlẹ Ọṣun, Amitolu Shittu, …
Read More »