Awọn eleyii ti rẹwọn he o, owo Naira tuntun ni wọn n ta n’llọrin 

Ibrahim Alagunmu, Ilọrin Ile-ẹjọ giga ijọba apapọ to fi ilu Ilọrin, ṣe ibujokoo ti sọ awọn…

Adajọ ti ni ki wọn lọọ da awọn afurasi mẹtala ti wọn pa ọba Koro ni Kwara ṣọgba ẹwọn 

Ibrahim Alagunmu, Ilọrin Lọjọ Iṣẹgun, ọjọ karun-un, oṣu Kẹta, ọdun 2024 yii, lawọn afurasi agbebọn mẹtala…

Ẹgbẹrun lọna aadọta Naira ni wọn fi mu mi wọnu iṣẹ ajinigbe-Abubakar  

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Ọmọkunrin ẹni ọdun mejilelogun kan, Musa Abubakar, ti sọrọ lori ọna to fi…

Lẹyin ọsẹ kan ti wọn sinku ọkọ ẹ, iyawo Akeredolu bẹrẹ ija buruku pẹlu ẹbi ọkọ rẹ

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Iyawo Gomina tẹlẹ ri nipinlẹ Ondo, Oloogbe Rotimi Akeredolu, Betty Akeredolu, tun ti…

Itiju nla ni pe orileede Ukraine fi agbado tọrẹ fun Naijiria nitori ebi! – Peter Obi

Faith Adebọla Yooba wọn, wọn lokun ọrun ko yẹ adiẹ, o si tun yẹ adiẹ, ko…

Iya awọn ọmọ mẹta to ku sinu mọto ti sọrọ: Indomie ti wọn maa jẹ ni mo lọọ mu ninu ṣọọbu- Silifat 

Ibrahim Alagunmu, Ilọrin Abilekọ Shade Silifat, iya awọn ọmọ mẹta to ku sinu mọto niluu Ilọrin,…

O ṣẹlẹ! Awọn araalu ya lọ sibi tijọba ko ounjẹ pamọ si l’Abuja, ni wọn ba ko gbogbo ẹ

Monisọla Saka Lagbegbe Phase 3, Abuja, lolu ilu orilẹ-ede yii, nibi ti ajọ to n ri…

Ọlọpaa tẹ eeyan mẹta pa, lawọn araalu ba binu lu meji pa ninu wọn

Lọjọ Ẹti, Furaidee, ọjọ kin-in-ni, oṣu Kẹta, ọdun 2024 yii, lawọn eeyan agbegbe Ikpeshi, nipinlẹ Edo,…

O ma ṣe o, abami kanga gbẹmi baba at’ọmọ pẹlu ẹni to fẹẹ yọ wọn

Adewale Adeoye Ko sẹni to maa ri i bi wọn ṣe n gbe oku baba, ọmọ ati gende kan…

Ọkọ mi ko lojuti, ko sibi ti ko le ki ‘kinni’ rẹ bọ bile ba da- Jane

Adewale Adeoye Iwaju Onidaajọ Doocivir Yawe, tile-ẹjọ kọkọ-kọkọ kan to wa lagbegbe Jikwoyi, niluu Abuja, ti i ṣe olu ilẹ wa, ni awọn tọkọ-taya meji…

Saheed Oṣupa sọrọ nipa ija oun ati Sunday Igboho

Faith Adebọla Titi dasiko yii ni awuyewuye ṣi n lọ lori ẹrọ ayelujara ati laarin awọn…