Jọkẹ Amọri Lẹyin to ṣabẹwo si gomina ipinlẹ Niger, Abubakar Sanni Bello, nibi to ti beere…
Category: Ìròyìn
Nitori ọrọ ti ko to nnkan, Usman pa ọmọọya kan naa mẹta ni Ṣaki
Ọlawale Ajao, Ibadan Ọjọ kẹẹẹdogun, oṣu kẹta, ọdun 2022 yii nile-ẹjọ sun ẹjọ ọkunrin ẹni ọgbọn…
Ti Buhari ko ba tete buwọ lu abadofin eto idibo ti wọn ṣatunṣe ẹ yii, ẹ fura si i – Ayọ Fayoṣe
Faith Adebọla Gomina ipinlẹ Ekiti tẹlẹ, Ọgbẹni Peter Ayọdele Fayoṣe, ti ke si Aarẹ orileede wa,…
L’Ọṣun, ori ko eeyan mejila yọ lọwọ iku ojiji
Florence Babaṣọla, Oṣogbo Eeyan mejila lo bọ lọwọ iku ojiji nibi ijamba ọkọ to ṣẹlẹ loju…
Ẹ maa dajọ iku fun ẹnikẹni to ba ti gbe oogun oloro – Oluwoo
Florence Babaṣọla, Oṣogbo Oluwoo ti ilẹ Iwo, Ọba Abdulrosheed Adewale Akanbi, ti sọ pe ọna kan…
Atẹnujẹ ko ba Peter, nitori to n mugbo, adajọ ni ko gba’lẹ kootu fọjọ marun-un
Florence Babaṣọla, Oṣogbo Ọdọmọkunrin kan, Peter Igwe, ladajọ kootu Majisreeti kan niluu Ileefẹ sọ pe ko…
Super Eagles gbo ewuro soju awọn agbabọọlu Guinea Bissau pẹlu ami-ayo meji si odo
Jọkẹ Amọri Ẹgbẹ agbabọọlu ilẹ wa, Super Eagles, ti gbo ewuro soju awọn akẹgbẹ wọn lati…
Famuyibọ fẹgbẹ APC silẹ l’Ekiti, o loun fẹẹ dije ninu ẹgbẹ Akọọdu
Taofeek Surdiq, Ado-Ekiti Oludije tẹlẹ ninu ẹgbẹ Social Democratic Party, Oloye Reuben Famuyibọ, ti fẹgbẹ Onigbaalẹ…
Mo maa sanwo WAEC awọn ọmọ yin tẹ ẹ ba fibo gbe mi wọle sipo aarẹ Naijiria
Adefunkẹ Adebiyi Aṣiwaju Bọla Ahmed Tinubu, baba to ti fi ẹrongba rẹ han lati dupo aarẹ…
Ijamba mọto paayan meji loju ọna Abẹokuta s’Ibadan
Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Eeyan meji lo doloogbe lọsan-an Ọjọruu, Wẹsidee, ọjọ kọkandinlogun, oṣu kin-in-ni, ọdun 2022…
Tọkọ-taya ko tọọgi lọọ lu tiṣa l’Ado-Odo, nitori ọmọ wọn tileewe ni ko gẹrun
Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Oju bọrọ ko gbọmọ lọwọ ekurọ lọrọ awọn akẹkọọ ileewe girama nipinlẹ Ogun…