Ibrahim Alagunmu, Ilọrin Ajọ ẹṣọ alaabo ṣifu difẹnsi, ẹka ti ipinlẹ Kwara, ti mu afurasi kan,…
Category: Ìròyìn
Alaga APC igun Oyetọla fun Arẹgbẹṣọla lesi, o ni ika, onigberaga ati alaimoore ni
Florence Babaṣọla, Oṣogbo Alaga ẹgbẹ oṣelu APC nipinlẹ Ọṣun, Ọmọọba Gboyega Famọdun, ti sọ pe ọrọ…
Ẹyin ọmọ Yoruba, ẹ jẹ ka ṣatilẹyin fun Tinubu – MC Oluọmọ
Faith Adebọla, Eko Alaga ẹgbẹ awọn onimọto l’Ekoo, Ọgbẹni Musiliu Akinsanya, tawọn eeyan mọ si MC…
Aṣiṣe nibọn wa to pa ọmọ ọdun meji n’Ilaro- Awọn aṣọbode
Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Ileeṣẹ aṣọbode ilẹ wa, ẹka ‘Ogun 1 Area Command’, ti ni awọn kabaamọ…
Gomina Seyi Makinde wọle pade pẹlu Ladọja, Lekan Balogun atawọn agba oye Ibadan
Ni Satide, ọjọ kẹẹẹdogun, oṣu kin-in-ni, ọdun yii, ni Gomina ipinlẹ Ọyọ, Ẹnjinnia Ṣeyi Makinde, tilẹkun…
Nitori to ṣe agbere, wọn fun iyaale ile lẹgba ọgọrun-un
Ọbẹ ti baale ile ki i jẹ, iyaale ile ko gbọdọ se e ni ọrọ wọn…
Eyi ni bi Akala ṣe fa mi goke laarin awọn olorin- Ayefẹlẹ
Ọlawale Ajao, Ibadan Gbajugbaja olorin Juju nni, Dokita Yinka Ayefẹlẹ, ti ṣalaye bi gomina ipinlẹ Ọyọ…
Mo maa n jẹ ẹya ara eeyan bii nnkan ọmọkunrin, oju, ifun ati gogongo, mo si tun maa n ta a fawọn to ba fẹ-Aminu
Aminu Baba lọkunrin to jokoo yii n jẹ, ẹnu ara ẹ lo fi jẹwọ pe oun…
Nitori ẹbun mọto tawọn ọmọ rẹ fun un lọjọọbi ẹ, Iya Fẹmi Adebayọ bu sẹkun
Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Inu ẹni ki i dun ka pa a mọra, koda, eeyan a maa…
Lẹyin tawọn Fulani yii sa lọgba ẹwọn Abolongo lọwọ tẹ wọn n’Isẹyin
Olu-Theo Omolohun, Oke-Ogun. Aṣeyọri nla ni fawọn ẹṣọ fijilante ilu Isẹyin, lagbegbe Oke-Ogun, nipinlẹ Ọyọ, latari bọwọ wọn ṣe…
Isọkusọ ọrọ ni pe mo ti fọwọ si Tinubu lati dupo aarẹ – Wọle Ṣoyinka
Faith Adebọla, Eko Onigege ara akọwe-kọwura ilẹ wa nni, Ọjọgbọn Wọle Ṣoyinka, ti sọ pe ọrọkọrọ…