Hijaabu: Ajọ CAN binu sijọba Kwara, wọn ni gbọgbọ ọna lawọn yoo fi ta ko wiwọ hijaabu lawọn ileewe awọn

Stephen Ajagbe, Ilorin Lẹyin tijọba ipinlẹ Kwara paṣẹ lọjọ Ẹti, Furaidee, pe awọn akẹkọọ-binrin to jẹ…

Ibadan lawọn Fulani ti jí Emmanuel gbe, ilu lsẹyin ni wọn lọọ ja a si lẹ́yìn ti wọn gbowo nla

Ọlawale Ajao, Ibadan   Leyin ọjọ mẹrin tó ti wa nígbèkùn àwọn ẹni ibi, ọmọ àgbẹ̀…

Nitori aabọ owo-osu to n san, ẹgbẹ oṣiṣẹ fẹẹ gbena woju Akeredolu l’Ondo

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ   Ẹgbẹ oṣiṣẹ ipinlẹ Ondo naa lawọn ti ṣetan ati gbena woju Gomina…

Ṣọja, ọlọpaa ati ọtẹlẹmuyẹ kọju ija si Sunday Igboho lọna Ibadan, wọn fẹẹ mu un tipatipa

Awọn ọlọpaa atawọn ẹṣọ agbofinro bii ogoji la gbọ pe wọn dena de ọkan ninu awọn…

Ijinigbe akẹkọọ Zamfara: Awọn obi fibinu ya bo ileewe, wọn ba dukia ijọba jẹ

Faith Adebọla Latari bawọn agbebọn ṣe ji awọn akẹkọọ-binrin to ju ọọdunrun lọ gbe nileewe ijọba…

Tori bi wọn ṣe n ji awọn akẹkọọ gbe, ẹgbẹ olukọ lawọn maa ti ileewe pa

Faith Adebọla       Pẹlu bi iṣẹlẹ jiji awọn ọmọleewe ati olukọ gbe lapa Oke-Ọya…

 Wọn ba oku ololufẹ meji ninu yara, wọn ni Sniper ni wọn mu

Ki i ṣe ayẹwo dokita lo fidi ẹ mulẹ pe awọn ololufẹ meji, Emmanuel Oshiotu, ẹni…

Awọn akẹkọọ Musulumi lẹtọọ si lilo hijaabu ni Kwara – Ijọba

Stephen Ajagbe, Ilorin   Ọrọ lilo ibori fun awọn akẹkọọ-binrin lawọn ileewe tawọn ajọ ẹlẹsin Kristẹni…

Iyawo fi háámà fọ adajọ lori, o lo n yan ọkọ oun lale

  Obinrin adajọ kan torukọ ẹ n jẹ Tamara Chibindi, ko ti i bọ ninu wahala to…

Lati ọdun 2017 ni ọta ibọn ọlọpaa ti wa lara mi – Teslim Ibitoye

Florence Babaṣọla Ọkunrin kan, Teslim Ibitoye, ti rawọ ẹbẹ si igbimọ tijọba ipinlẹ Ọṣun gbe kalẹ…

Awọn nọọsi fun Akeredolu lọjọ mẹta ki wọn too bẹrẹ iyansẹlodi l’Ondo

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ     Lẹyin bii osu kan tawọn dokita ti bẹrẹ iyansẹlodi ọlọjọ gbọọrọ…