Aṣiri tu, eyi nidi ti ijọba orileede Benin fi ju Sunday Igboho sọgba ẹwọn

Jọkẹ Amọri Latigba ti wahala to ṣẹlẹ lorileede Benin, lọgunjọ, oṣu keje yii, nibi ti wọn…

Baalẹ ilu dero ahamọ ọgba ẹwọn, wọn lọ lu jibiti miliọnu meji naira

Ọlawale Ajao, Ibadan Nitori ti wọn lo lu ẹnikan ni jibiti miliọnu meji naira, baba kan…

Ọba tuntun jẹ ni Lafiagi 

Ibrahim Alagunmu, Ilọrin Ọjọruu, Wẹsidee, ọṣẹ yii, ni igbimọ afọbajẹ niluu Lafiagi kede Muhammed Kawu, gẹgẹ…

Jamiu ba aṣẹwo lo pọ tan, lo ba gun un lọbẹ pa l’Abẹokuta

Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Jamiu Malọmọ lọmọkunrin yii n jẹ, ọmọ ọdun mejidinlogun pere ni (18), ṣugbọn…

Ile ti Ayọmide ti lọọ ṣiṣẹ lo ti ji jẹnẹretọ, ọwọ Amọtẹkun ti tẹ oun ati Hausa to ta a fun l’Oṣogbo

Florence Babaṣọla, Oṣogbo Ọmọdekunrin kan, Ayọmide Akande, ti n ran awọn oṣiṣẹ ajọ ọtẹlẹmuyẹ nipinlẹ Ọṣun…

O ma ṣe o, ọmọ ọdun mẹrin ja si ṣalanga lasiko ti wọn n gba bọọlu l’Ekiti

Taofeek Surdiq, Ado-Ekiti Inu ipayinkeke ati ibanujẹ ni obi ọmọ ọdun mẹrin kan wa bayii pẹlu…

Nitori ẹsun magomago, EFCC gbẹsẹ le akaunti ileegbimọ aṣofin Ọyọ

Ọlawale Ajao, Ibadan Ajọ to n gbogun ti iwa jibiti ati ṣiṣe owo ilu baṣubaṣu (EFCC),…

Ipinlẹ Ọṣun ni Sẹfiu atawọn ọrẹ rẹ ti digun ja pasitọ lole, ipinlẹ Ogun lọwọ ti tẹ wọn

Florence Babaṣọla, Oṣogbo Kọmiṣanna ọlọpaa nipinlẹ Ọṣun, Wale Ọlọkọde, ti ṣafihan ikọ adigunjale ẹlẹni-mẹta kan lọjọ…

Kootu fẹẹ pe Yọmi Fabiyi lẹjọ nitori sinima ‘Ọkọ Iyabọ’

Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Ẹka ti wọn ti n ri si ipẹjọ lawọn kootu Eko (Directorate of…

Nitori ẹsun jibiti ori ẹrọ ayelujara, adajọ sọ akẹkọọ Fasiti Ilọrin, KWASU ati Kwara Poly sẹwọn n’llọrin

Ibrahim Alagunmu, Ilọrin Adajọ  Mahmood Abdulgafar tile-ẹjọ giga kan ni Ilọrin, nipinlẹ Kwara, ti sọ  Abubakar…

Ki Buhari kuro nipo lai fakoko ṣofo, o to gẹẹ-Abubakar Gumi

Faith Adebọla Ilu-mọ-ọn-ka aṣaaju ẹsin Musulumi lapa Oke-Ọya nni, Sheikh Abubakar Gumi, ti takoto ọrọ ṣọwọ…