Faith Adebọla, Eko Awọn gomina ilẹ Yoruba ti dabaa pe kawọn aṣofin ṣatunṣe si ofin ilẹ…
Category: Ìròyìn
Iwa tawọn tawọn DSS hu si Sunday Igboho le ṣakoba fun iṣọkan orilẹ-ede Naijiria-Awọn ọba Yoruba
Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Ajọ awọn lọbalọba ilẹ Yoruba ti koro oju si bi ijọba apapọ ṣe…
Ahmed Musa, agbabọọlu ilẹ wa, fẹyawo keji
Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Agbami ifẹ ẹlẹẹkeji ni agbabọọlu ilẹ wa nni, Ahmed Musa, ti n luwẹẹ…
Papa iṣere Ilọrin la ti maa ṣe ayẹyẹ ‘Durbar’ ọdun yii – Ilọrin Emirate
Ibrahim Alagunmu, Ilọrin Awọn igbimọ to n mojuto bi ayẹyẹ Durbar to maa n waye niluu…
Gbogbo Ọjọbọ, Tọsidee, lawọn oṣiṣẹ yoo fi maa wọṣo adirẹ nipinlẹ Ọṣun bayii
Florence Babaṣọla, Oṣogbo Gomina ipinlẹ Ọṣun, Alhaji Adegboyega Oyetọla, ti kede pe ṣiṣẹ aṣọ adirẹ lọpọ…
Tori arun Korona to tun n yọju, Sanwo-Olu ni kawọn ileejọsin ati ibi ariya din ero ku
Faith Adebọla, Eko Yoruba bọ, wọn ni ifura loogun agba, ijọba ipinlẹ Eko ni toju tiyẹ…
Awọn ajinigbe yinbọn pa Olori-ọdọ n’Ibadan
Ọlawale Ajao, Ibadan Awọn ajinigbe tun ṣe bẹbẹ n’Ibadan lọjọ Abamẹta, Satide, pẹlu bi wọn ṣe…
Sound Sultan, olorin taka-sufee, ku lojiji
Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Abduganiu Ọlanrewaju Fasasi gan-an lorukọ ẹ, ṣugbọn Sound Sultan lọpọ eeyan mọ ọkunrin…
Eyi ga o, wọn tun ji Emir atawọn eeyan mẹwaa mi-in gbe ni Kaduna
Faith Adebọla Afaimọ ki ipinlẹ Kaduna ma gba oye ipinlẹ ti aabo rẹ mẹhẹ ju lọ…
Ọpẹ o, wọn ti ri awọn agbẹ mẹrin ti wọn ji gbe ni Ikosun-Ekiti
Taofeek Surdiq, Ado-Ekiti Awọn ọlọpaa nipinlẹ Ekiti ni Satide, ọjọ Abamẹta, ti kede pe awọn ti…
Bireeki tanka epo feeli, lo ba tẹ awọn ọmọleewe mẹẹẹdogun pa
Faith Adebọla Iran buruku ni iran ọhun, iran ti ko dun un wo rara, tori teeyan…