O ma ṣe o, ọkọ akoyọyọ tẹ ọlọkada meji pa l’Akurẹ

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Awọn meji ni wọn pade iku ojiji lọjọ Aiku, Sannde ọsẹ yii, pẹlu…

Amotẹkun ti mu awọn Fulani to fipa ba awọn obinrin ti wọn ji gbe lo pọ l’Akurẹ

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Awọn ajinigbe mẹrin kan lọwọ ẹsọ Amọtẹkun ipinlẹ Ondo tẹ niluu Akurẹ lọjọ…

Ole meji ku soju ija ni Ṣagamu, awọn ọlọpaa lo yinbọn fun wọn

Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Lọjọ Aiku, Sannde, ọsẹ yii, lawọn ole meji kan ku ni lairo tẹlẹ.…

Naijiria o le wa niṣọkan labẹ ijọba Buhari yii – Wọle Ṣoyinka

Faith Adebọla, Eko Ogbontarigi onkọwe to dantọ ni, Ọjọgbọn Wọle Ṣoyinka, ti sọ pe ko si…

Awọn ọba Amosun yari fun igbimọ Oloye Kemta, wọn lawọn o ki i ṣe baalẹ, Tẹjuoṣo naa loun ṣi ni Olu Orile-Kemta

Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Latari bi igbimọ Oloye Kemta(Kemta Council Of Chiefs) nipinlẹ Ogun, ṣe ni awọn…

Mi o bu Pasitọ Adeboye o, awọn alabosi lo n sọsọkusọ kiri – Sunday Igboho

Faith Adebọla Ilu-mọ-ọn-ka ajijagbara ilẹ Yoruba nni, Sunday Adeyẹmi, ti inagijẹ rẹ n jẹ Sunday Igboho…

Aṣegbe o si fẹnikẹni to ba pa Fulani, tọhun maa san gbese ẹ dandan ni – Gomina El-Rufai

Faith Adebọla Gomina ipinlẹ Kaduna, Mallam Nasir El-Rufai, ti sọ pe dandan ni kawọn Fulani gbẹsan…

 Awọn Fulani darandaran kọ lu agbẹ meji ninu oko l’Ẹrinle

Stephen Ajagbe, Ilorin Awọn agbẹ meji; Joseph Goje ati Nathaniel Goje, ti wọn fi ilu Ọyan,…

Sunday Igboho yari: A maa bẹrẹ si i wọgbo lọọ ba awọn Fulani kaakiri ilẹ Yoruba

Faith Adebọla Gbajugbaja ajijagbara ilẹ Yoruba nni, Sunday Adeyẹmọ, ti gbogbo eeyan mọ si Sunday Igboho,…

Wọn ti ju wolii to wọn lọfinda sara Kayọde tina fi jo o pa ni ṣọọṣi Sẹlẹ satimọle

Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Lẹyin iku ojiji to pa ọkunrin kan, Kayọde Badru, to ṣẹṣẹ ti Dubai…

Awọn alailaaanu ọmọ Naijiria kan lo fẹẹ doju ijọba mi de

Faith Adebọla Aarẹ orileede yii, Ajagun-fẹyinti Muhammadu Buhari, ti sọ pe o ṣi n ya oun…