Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Ọkan-o-jọkan oko ọrọ lawọn asaaju PDP ipinlẹ Ondo n sọ lu ara wọn…
Category: Ìròyìn
Ki laa ti waa ṣeyi si, awọn Fulani tun pa agbẹ meji n’Igangan
Ọlawale Ajao, Ibadan O kere tan, eeyan meji lo ku, tọpọ eeyan si fara pa nigba…
Ajiṣafẹ dero ẹwọn, orukọ ọga FRSC lo fi lu jibiti l’Omu-Aran
Stephen Ajagbe, Ilorin Ajiṣafẹ Tokunbọ, oṣiṣẹ ajọ to n mojuto igboke-gbodo ọkọ, FRSC, tẹlẹ, ti wa…
Lẹyin ti wọn dana sun ẹni kan laaye, wọn tun yinbọn paayan mi-in n’Ibadan
Ọlawale Ajao, Ibadan Laarin wakati mélòó kan sira wọn, èèyàn meji ni won ti pa nipakupa…
Fidio: Ẹ woju Aafaa Awayewaserere to n ra ori eeyan niluu Iwo
Orukọ ko ro ọkunrin to pe ara rẹ ni Aafaa Awayewaṣerere yii o. Ẹ gbọ iye…
Eyi nidi ta a fi le awọn ẹṣọ Amọtẹkun meje danu n’Ibadan- Ọlayinka
Ọlawale Ajao, Ibadan Oludari ikọ ẹ̣sọ eleto aabo ilẹ Yoruba, Amọtẹkun, ẹka ipinlẹ Ọyọ, Ajagunfẹyinti…
Igbimọ oluwadii ifiyajẹni SARS ni kawọn ọlọpaa mẹrin fara han kiakia l’Ọṣun
Florence Babaṣọla, Oṣogbo Igbimọ tijọba ipinlẹ Ọṣun gbe kalẹ lati ṣewadii oniruuru ẹsun ti awọn araalu…
Awọn ajinigbe ji oṣiṣẹ-fẹyinti gbe ni Kwara
Stephen Ajagbe, Ilorin Lẹyin ọjọ kan tawọn ajinigbe ji Hakeem Ojo pẹlu baba agbalagba kan lọna…
Gomina gboriyin fawọn obinrin to dawo kọ ileewe ni Kwara
Stephen Ajagbe, Ilorin L’Ọjọbọ, Tọsidee, ọsẹ yii, Gomina Abdulrahman Abdulrazaq tipinlẹ Kwara ṣabẹwo si ileewe…
Akẹkọọ Fasiti ipinlẹ Eko mẹta lugbadi Korona, lawọn alaṣẹ ba ti ile ti wọn n gbe pa
Faith Adebọla, Eko Latari bi esi ayẹwo ti wọn ṣe fawọn kan lara awọn akẹkọọ Fasiti…
Nitori ti won ko lo ibomu, awọn alaṣẹ ileewe le akẹkọọ meji danu nipinlẹ Ọyọ
Ọlawale Ajao, Ibadan Nitori ti wọn ko lo ibomu lati daabo bo ara wọn kuro…