Faith Adebọla, Eko Ibi tawọn afurasi adigunjale meji kan, Ọpẹyẹmi Adegboyega, ẹni ọdun mejidinlọgbọn, ati…
Category: Ìròyìn
Ọjọ mẹfa ni mo fi sun inu igbó lahaamọ awọn Fulani ajinigbe- Alaga kansu
Ọlawale Ajao, Ibadan Alaga ijọba ibilẹ onidagbasoke Iganna, lagbegbe Ibarapa, nipínlẹ Ọyọ, Ọnarebu Ọlayiwọla Adeleke,…
Dubai lawọn eleyii ti waa ṣe ‘Yahoo’ l’Ekoo ti EFCC fi mu gbogbo wọn
Faith Adebọla, Eko Orileede United Arab Emirates, ti Dubai jẹ olu-ilu rẹ, ni wọn lawọn…
”Igbẹ lawọn Fulani to ya wọ lbarapa waa dẹ lati ipinlẹ Kebbi”
Ọlawale Ajao, Ibadan Ọpọ èèyàn niṣẹlẹ ọhún ko laya soke nigba ti iroyin lu jade pe…
Kọmiṣanna ọlọpaa Eko ṣekilọ fawọn ọba alaye: Ẹ yee ṣonigbọwọ fawọn ọmọ ẹgbẹ okunkun
Faith Adebọla, Eko Kọmiṣanna ọlọpaa ipinlẹ Eko, CP Hakeem Odumosu, ti fi aidunnu…
Ọọni Adeyẹye ranṣẹ ikilọ pataki si Sunday Igboho
Jide Alabi Pẹlu bi nnkan ṣe n lọ yii, Ọọni Ile-Ifẹ, Ọba Adeyẹye Ogunwusi, ti…
Peter sọ fawọn ọrẹ ẹ pe ọga oun lowo lọwọ, n l’Arowolo atawọn ẹgbẹ ẹ ba lọọ digun ja a lole l’Ekoo
Aderounmu Kazeem Bii ajẹ to jẹ̣ eepo ọbọ ni ọdomọkunrin kan, Arowolo Ibrahim, ṣe n…
Lucky ati Sheriff, ọmọ ẹgbẹ okunkun Ẹiyẹ, ko sọwọ ọlọpaa n’lkorodu
Faith Adebọla, Eko Ọwọ ọlọpaa ti ba awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun meji kan, Sheriff…
Awakọ pa oṣiṣẹ LASTMA l’Ekoo
Jide Alabi L’Ọjọruu, Wẹsidee, ọsẹ yii ni ẹṣọ agbofinro to n dari ọkọ, iyẹn LASTMA pade…
Awọn ṣọja dawọọ idunnu lori bijọba ṣe yọ Buratai, olori wọn tẹlẹ
Faith Adebọla Fọnran fidio kan to gori atẹ ayelujara lafẹmọju Ọjọruu, Wẹsidee, ti ṣafihan bi awọn…
Tunde Bello ti wọn lo fipa ba obinrin sun lẹyin to ji i gbe ti wa l’Eleweeran
Aderounmu Kazeem L’Ọjọruu, Wẹsidee, ni olu ileeṣẹ ọlọpaa to wa ni Eleweran niluu Abẹokuta, ipinlẹ Ogun,…