Faith Adebọla Niṣe ni ọkunrin afurasi ọdaran yii, Imran Taofeek Ọlalekan, ẹni ọdun mẹrinlelogoji (44), lanu…
Category: Ìròyìn
Aadọta miliọnu lawọn ajinigbe to ji akẹkọọ Fasiti Taraba meji n beere fun
Adewale Adeoye Miliọnu lọna aadọta Naira (N50M) lawọn ajinigbe kan ti wọn ji akẹkọọ ileewe Fasiti Taraba ‘Federal University’, to wa lagbegbe Wukari, nipinlẹ Taraba, n beere…
Lẹyin ti baale ile yii pa iyawo ẹ tan loun naa gbe majele jẹ
Adewale Adeoye Ha-in lọrọ oṣiṣẹ banki kan, Oloogbe Mike Illishebo, ẹni ọdun mẹrinlelogoji, to pa iyawo rẹ, Valeria Franco, ẹni ọdun marundinlogoji, ṣi n…
Ojo nla ṣọṣẹ ni Poli Ekiti, ọpọlọpọ nnkan lo bajẹ
Taofeek Surdiq, Ado-Ekiti Kayeefi nla lo jẹ fun gbogbo eeyan ipinlẹ Ekiti l’Ọjọbọ, Wẹsidee, ọjọ kẹta,…
Ọpọlọpọ egboogi oloro ti ọmọkunrin yii fẹẹ gbe sọda siluu oyinbo lo ti ya jade lakata NDLEA
Monisọla Saka Ọwọ ajọ to n gbogun ti tita, rira ati lilo egboogi oloro nilokulo lorilẹ-ede…
Ibọn onike lawọn eleyii fi n jale tọwọ fi tẹ wọn
Adewale Adeoye Ọdọ awọn ọlọpaa agbegbe Isọkoko, ni Agege, nipinlẹ Eko, lawọn gende meji kan, Kyari Idris, ẹni ogun ọdun, ati Abubarkar Salisu, ẹni ọdun mejidinlogun wa. Ẹsun ti wọn…
Nitori foonu, ṣọja ati olotẹẹli fiya jẹ ọmọkunrin yii titi to fi ku
Monisọla Saka Ọwọ awọn agbofinro ipinlẹ Imo ti tẹ Ọgbẹni Ibe Obasi, ọkunrin to ni ile…
Ijọba apapọ kede ọjọ Iṣẹgun ati Ọjọruu gẹgẹ bii isinmi ọdun itunu aawẹ
Adewale Adeoye Ijọba orileede Naijiria ti kede ọjọ Iṣẹgun, Tusidee, ọjọ kẹsan-an, ati Ọjọruu, Wẹsidee, ọjọ…
Eyi lawọn ohun to yẹ ki ẹ mọ nipa afikun owo ina mọnamọna
Monisọla Saka Ileeṣẹ to n ri si ọrọ ina mọnamọna lorilẹ-ede yii, Nigerian Electricity Regulatory Commission…
‘’Iya gidi ni yoo jẹ ọlọpaa to ba yẹ foonu araalu wo loju titi’’
Monisọla Saka Ileeṣẹ ọlọpaa ilẹ wa, ẹka ti ipinlẹ Edo, ti ṣe e leewọ fawọn agbofinro…
Wọn ti mu Pasitọ James to lu ọmọ ijọ rẹ ni jibiti owo nla n’llọrin
Ibrahim Alagunmu, Ilọrin Ọwọ ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ ati ṣiṣe owo ilu mọku-mọku…