Ẹyin tẹ ẹ ba fẹẹ kopa ninu idije ibalopọ pẹlu ẹbun nla, ẹ maa bọ o

Monisọla Saka Gbogbo ẹyin ọmọ Naijiria tẹ ẹ ba mọ pe ẹ da ara yin loju…

Nitori ẹsun pe o n ṣẹgbẹ okunkun, Kwara Poli gba iwe-ẹri akẹkọọ wọn kan pada 

Ibrahim Alagunmu, Ilọrin Awọn alaṣẹ ileewe gbogbonise tipinlẹ Kwara, Kwara State Polytechnic, ti kede lọjọ Aje,…

Wahala n bọ laarin ijọba Sanwoolu ati Iyabọ Ojo o!

Adewale Adeoye Ni bayii, awọn alaṣẹ ijọba ipinlẹ Eko ti fun gbajumọ aṣere tiata ilẹ wa…

Ọmọọdun mejidinlogoji di olori awọn aṣofin Ọṣun

Florence Babaṣọla, Oṣogbo Awọn aṣofin ipinlẹ Ọṣun ti yan ọkan lara wọn, Adewale Ẹgbẹdun, lati ijọba…

Iru ki waa leleyii! Wọn yinbọn pa olukọ Fasiti Ibadan

Ọlawale Ajao, Ibadan Inu ọfọ lawọn alaṣẹ, oṣiṣẹ atawọn akẹkọọ Fasiti Ibadan (University of Ibadan), wa…

Ẹgbẹ oṣiṣẹ lawọn ko daṣẹ silẹ mọ

Adewale Adeoye Lẹyin ipade oniwakati gbọọrọ kan to waye laarin aṣoju ijọba apapọ orileede yii atawọn…

Nitori wahala owo iranwọ epo, gomina ni kawọn oṣiṣẹ maa wabi iṣẹ lọjọ mẹta ni Kwara

Ibrahim Alagunmu, Ilọrin Ijọba ipinlẹ Kwara, labẹ iṣejọba Gomina Abdulraman AbdulRazaq, ti ṣe ipade pẹlu awọn…

Awọn oṣiṣẹ kootu naa lawọn maa daṣẹ silẹ o

Adewale Adeoye A n pe ọrọ ọhun lọwẹ, o n laro ninu o, bii ere, bii…

Bi Tinubu ba pe mi lati ba a ṣisẹ, ma a kọkọ gba iyọnda lọwọ awọn eeyan wọnyi-Wike

Adewale Adeoye Gomina ipinlẹ Rivers tẹlẹ, Ọgbẹni Nysom Wike, ti sọ pe ki i ṣe pe…

Nitori ọrọ owo iranwọ epo bẹntiroolu, Falana ṣabẹwo si Tinubu

Monisọla Saka Lọjọ Abamẹta, Satide, ọjọ kẹta, oṣu Kẹfa, ọdun yii, ni agba agbẹjọro nilẹ wa…

Ijọ Katoliiki Ondo ṣeranti ọdun kan tawọn agbebọn waa paayan rẹpẹtẹ nibẹ

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Ọjọ Aje, Mọnde, ọjọ karun-un, oṣu Kẹfa, ọdun 2023 yii, ni gbogbo ọmọ…