Wọn ti mu Adamu o, maaluu mẹtalelogun lo lọọ ji ko

Monisọla Saka Ọwọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Gombe, ti tẹ afurasi ọdaran kan, Adamu Maikudi, ẹni ọdun…

 Eedi ree o! Ibọn ọlọdẹ ṣeeṣi yin, o pa ọmọde mẹta, awọn mẹrin wa nileewosan

Adewale Adeoye Awọn ọdọmọde mẹta lo ku, awọn mẹrin mi-in fara pa yannayanna lasiko ti ibọn ọlọdẹ kan ṣeeṣi…

Iya Mohbad yari kanlẹ: Ayẹwo ẹjẹ ọmọ oloogbe ko kan araalu, ọrọ ẹbi wa ni

Adewale Adeoye Pẹlu ọrọ ti Abilekọ Abọsẹde Adeyẹmọ, iya to bi gbajumọ akọrin nni, Oloogbe Ilerioluwa Alọba, ẹni tawọn eeyan mọ si Mohbad, sọ laipẹ yii, o daju pe ọrọ ayẹwo ẹjẹ fọmọ oloogbe naa ṣi maa…

Nibi ti ọmọkunrin yii ti n mura ati se ẹran ẹlẹran to ji gbe lawọn ọlọpaa ti mu un

Adewale Adeoye Ọdọ awọn ọlọpaa agbegbe Kurikyo, nijọba ibilẹ Lafia, nipinlẹ Nasarawa, ni Ọgbẹni Mohammed Tanko, ẹni ti wọn fẹsun kan pe o lọọ ji ẹran agbo nla kan…

Wọn ti mu Balogun o, ayederu ṣọja to n faṣọ ijọba lu jibiti l’Ekoo

Adewale Adeoye Lagbegbe Isheri-Ọṣun, nipinlẹ Eko, lọwọ awọn ọlọpaa ti tẹ ayederu ṣọja kan to pe ara rẹ ni Sajẹnti Major Fẹmi Balogun, pẹlu aṣọ ijọba lọrun…

Wahab yii ma laya o, ọlọpaa lo fẹẹ ja lole ti wọn fi mu un

Adewale Adeoye Afurasi adigunjale kan, Akinjọbi Wahab, ẹni ọdun mọkandinlogun, ti ṣi iṣẹ ṣe bayii o. Ọlọpaa ti ko wọsọ…

Kindinrin eeyan mẹta, ọkan mẹta, eegun ẹyin ati ahọn ni wọn ba lọwọ Aafaa Idris l’Akoko

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Aafaa kan ti wọn porukọ rẹ ni Oluwafẹmi Idris, lọwọ ti tẹ l’Akoko,…

Eyi lohun to wa laarin emi ati Olubadan to waja- Ọbasanjọ

Ọlawale Ajao, Ibadan Yatọ si pe “Ẹgbọn mi”, “Ẹgbọn mi” l’Olubadan to waja, Ọba Mohood Ọlalekan…

Nitori obinrin, ṣọja gun ọmọkunrin yii pa m’ọnu ṣọọbu rẹ l’Akurẹ

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ  Ọkunrin oniṣowo kan, Ezeani Ebuka, ni ṣọja kan ti gun lọbẹ pa mọ’nu…

Ọpẹyẹmi tan ọrẹ ẹ lọ sinu igbo, lẹyin to pa a tan lo ji ọkada rẹ gbe lọ l’Ondo

Oluṣẹyẹ Iyiade Ọwọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ondo ti tẹ ọkunrin kan, Dọlapọ Babalọla, lori ẹsun ṣiṣeku…

Ezekiel, ọmọ ọdun mẹwaa, pa ọrẹ rẹ lasiko ti wọn n gba bọọlu l’Ekoo

Adewale Adeoye Ọdọ awọn alaṣẹ ileeṣẹ ọlọpaa agbegbe Ejigbo, nipinlẹ Eko, ni ọmọ ọdun mẹwaa kan, Evbota Ezekiel, to pa ọrẹ rẹ, Oloogbe Israel Ogunlẹyẹ, ẹni ọdun mẹwaa, wa bayii,…