Nitori ẹsun wiwa kusa lọna aitọ, afurasi marun-un ha ṣakolo EFCC n’llọrin 

Ibrahim Alagunmu, Ilọrin Akolo ajọ to n gbogun ti iwa jibiti ati ṣiṣe owo ilu mọkumọku…

O ma ṣe o, oludije funpo gomina lẹgbẹ APC Ondo ku lojiji

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Kayeefi patapata lọrọ iku Dokita Paul Akintẹlurẹ, to jẹ ọkan pataki ninu awọn…

Iṣana ti wọn fi n tan gaasi l’Ayinde n lo bii ibọn lati jale l’Ado-Odo

Faith Adebọla  Beeyan ko ba wo kinni naa daadaa, ibọn gidi ni tọhun yoo kọkọ pe…

O ma ṣe o, tirela Dangote pa obinrin kan lẹgbẹẹ titi l’Abule-Ẹgba

Faith Adebọla Ọkọ ajagbe, iru eyi ti wọn fi maa n ko simẹnti lẹbulẹbu, to jẹ…

Adeleke fi ipilẹ ile awọn alalaaji lelẹ l’Ọṣun

Florence Babaṣọla, Oṣogbo Lati le mu ki irinajo si ilẹ mimọ Saudi Arabia rọrun fun awọn…

Nitori ọrọ aṣọ lasan, Jimoh lu Abubakar pa n’llọrin, lo ba sa lọ 

Ibrahim Alagunmu, Ilọrin Iwadii gidi ti bẹrẹ lori idi ti Ọmọtọṣọ Jimoh, ṣe lu ọkunrin kan,…

O ṣẹlẹ, ijọba ti mu Gumi, wọn ni ko waa sọ tẹnu ẹ lọdọ awọn ọtẹlẹmuyẹ

Faith Adebọla Ijọba apapọ orileede yii ti ke si gbajugbaja olukọ ẹsin Islam lapa Oke-Ọya, to…

Ijọba ko san kọbọ fawọn ajinigbe ti wọn fi tu awọn akẹkọọ Kaduna silẹ – Minisita eto ẹkọ

Faith Adebọla Minisita feto ẹkọ nilẹ wa, Ọjọgbọn Tahir Mamman, ti sọ pe lọfẹẹ-lofo lawọn ajinigbe…

Iya Mohbad tu aṣiri mi-in nipa iku ọmọ ẹ

Faith Adebọla Abilekọ Abọsẹde Alọba, ti i ṣe iya gbajugbaja onkọrin hipọọpu nni, Ilerioluwa Ọladimeji Alọba,…

O ma ṣe o, ina jo akẹkọọ ileewe fasiti meji pa

Adewale Adeoye Beeyan ba jori ahun, to ba ri bi ina ṣe jo meji lara awọn…

O ma ṣe o! Nibi tọkunrin oloṣelu yii ti n kirun lawọn agbebọn pa a si

Monisọla Saka Ọkunrin oloṣelu kan ti wọn pe orukọ rẹ ni Alaaji Lado, ti ki aye…