Awọn agbebọn pa ọlọde mẹrin, wọn tun ji ọmọ olori ilu gbe sa lọ

Adewale Adeoye Nnkan ko fara rọ l’Ọjọbọ, Tọsidee, ọjọ kejidinlogun, oṣu Kẹrin, ọdun yii, lasiko tawọn agbebọn kan ya wọnu ilu…

O ma ṣe o, ijamba ọkọ fẹmi eeyan mejila ṣofo

Adewale Adeoye Beeyan ba jẹ ori ahun to ba ri bi awọn oṣiṣẹ ajọ ẹṣọ oju popo, ‘Federal Road Safety Corps’ (FRSC), ẹka tipinlẹ Kano, ṣe n fa…

O ma ṣe o! Ijamba ọkọ gbẹmi akẹkọọ Poli l’Ọṣun

Florence Babaṣọla, Oṣogbo Dẹrẹba ọkọ kan to ti sa lọ bayii la gbọ pe o ṣokunfa…

Ṣẹyin naa ti gbọ! EFCC n wa Yahaya Bello gidigidi

Monisọla Saka Ajọ to n gbogun ti iwa jẹgudujẹra, ṣiṣe owo ilu mọkumọku ati ẹsun mi-in…

Awọn ole wan ṣansi wọ bii miliọnu meji lakaunti ẹni ti wọn gbe

Monisọla Saka Ọwọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko, ẹka teṣan Ilasan, ti tẹ afurasi mẹrin kan, nitori…

Wọn ti mu Saliu to lọọ jale nile onile n’Ilọrin

Ibrahim Alagunmu, Ilọrin Akolo ileeṣẹ ọlọpaa ẹka tipinlẹ Kwara, ni awọn afurasi meji kan, Ọlarewaju Saliu…

Nitori Bobrisky, oṣere yii sọko ọrọ sawọn onitiata ẹgbẹ ẹ

Monisọla Saka Ọkan lara awọn oṣerekunrin ilẹ wa, Alesh Sanni, ti bu ẹnu atẹ lu iwa…

 Nitori ofin tijọba fi de nina owo Naira loju agbo, Portable yari fun EFCC

Monisọla Saka Gbajumọ olorin taka-sufee ilẹ wa tẹnu rẹ ki i dakẹ nni, Habeeb Okikiọla Ọmọlalọmi,…

Abẹẹ ri Wasiu, niṣe lo jira rẹ gbe pamọ n’llọrin, lo ba n beere owo itusilẹ lọwọ obi ẹ 

Ibrahim Alagunmu, Ilọrin Ọwọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Kwara ti tẹ gende-kunrin kan, Wasiu Afọlabi, ẹni ọdun…

Ondo ni wọn ti mu baale ile kan to pa iyawo rẹ ni Adamawa

Adewale Adeoye Ipinlẹ Ondo lawọn alaṣẹ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Adamawa ti pada mu baale ile kan, Ọgbẹni Riba Kwanta, ẹni ogoji ọdun to n gbe…

Ara kenge, obinrin yii gbe oku aburo baba rẹ lọ si banki lati fi ṣe oniduuro

Adewale Adeoye Ọdọ awọn ọlọpaa agbegbe Rio de Janeiro, lorileede Brazil, ni iyaale ile kan, Abilekọ Erika De Souza Nunes,…