Kalu to yinbọn lu Adija nitori ounjẹ l’Abẹokuta ti wa lẹwọn

Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Kootu Majisireeti to n jokoo l’Abẹokuta ti paṣẹ pe ki wọn ju ọkunrin…

Ṣoworẹ atawọn ọdọ tun ṣewọde l’Abuja, wọn ni dandan ni ki Buhari lọ

Faith Adebọla  Ọjọ Aje ti kaluku n gba ọna iṣẹ aje lọ lọjọ Mọnde, ṣugbọn niṣe…

Ẹ wo Adeṣina to fipa ba iya ọgọta ọdun lo pọ n’Idanyin

Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Adeṣina Adebọwale lorukọ ọkunrin yii, ẹni ogoji ọdun ni. Ọjọ Sannde ọsẹ yii…

Ko sẹni to le da wa duro, iwọde Yoruba Nation maa waye l’Ekoo loṣu keje

Faith Adebọla Bi ko ba si ayipada, ọjọ Abamẹta, Satide, ọjọ kẹta, oṣu keje, to n…

Abayọmi  to n ta oogun oloro fawọn akẹkọọ FUNAAB bọ sọwọ NDLEA l’Abẹokuta

Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Ọkunrin kan, Abayọmi Popoọla, to n gbe niluu Eko, ṣugbọn to maa n…

Abimbọla at’ọrẹkunrin ẹ lọọ sa pamọ I’Ekiti, ni wọn ba ranṣẹ sile pe wọn ji awọn gbe

 Taofeek Surdiq, Ado-Ekiti Fun dida ọgbọn alumọkọrọyi lati gba owo lọwọ awọn obi wọn, awọn ololufẹ…

Awọn agbebọn kọ lu teṣan ọlọpaa ni Benue, wọn ba pa mẹrinla ninu wọn

Faith Adebọla Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Benue ti fidi ẹ mulẹ pe ohun ti awọn agbebọn kan…

Nibi ti kọsitọọmu at’onifayawọ ti n bara wọn ja ni wọn ti yinbọn pa ọmọọlewe kan ni Badagry

Faith Adebọla, Eko Ibanujẹ ati ọfọ nla ti ṣẹlẹ sawọn mọlẹbi akẹkọọ ọmọ ọdun mejidinlogun kan,…

Tọpẹ Alabi dupẹ lọwọ gbogbo awọn ololufẹ ẹ fun aduroti wọn

Faith Adebọla Latari awuyewuye to waye lọsẹ to kọja lori ọrọ abuku to sọ nipa orin…

Ohun kan ṣoṣo ti mo fẹ ni kijọba gbẹsan lara awọn to ṣeku pa ọmọ mi-Iya Ramon

Faith Adebọla Alaaja Salimọt Azeez, iya ọkunrin ẹni ọdun mẹtadinlogoji kan, Ramon Azeez, ti wọn fibọn…

Ajagungbalẹ mẹta ko sọwọ ọlọpaa l’Odogbolu

Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Bi awọn ọkunrin yii ṣe ti wa ni ahamọ awọn ọlọpaa, lẹka itọpinpin,…