Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Iwọde ti wọn ti n kede rẹ pe yoo waye kaakiri awọn ipinlẹ…
Awọn ọdọ ṣewọde ‘June 12’ l’Ọjọta, lawọn ọlọpaa ba kọ lu wọn
Faith Adebọla, Eko Paroparo ni ọpọ agbegbe da niluu Eko, pẹlu bawọn araalu ṣe fidi mọle…
Awọn eeyan n ba iṣẹ aje wọn lọ ni Kwara, ko si iwọde “June 12”
Ibrahim Alagunmu, Ilorin Gbogbo awọn iyalọja, kẹkẹ Maruwa, ọlọkada atawọn oniṣẹ ọwọ, ni wọn n ba…
Dapọ Abiọdun ko ọpọlọpọ mọto fawọn ọlọpaa nitori iṣẹ aabo
Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Ko din ni mọto ayọkẹlẹ marundinlogoji (35), ọkọ akero-kẹru ogun (20), ẹwu akọtami…
Awọn olọja ti ṣọọbu pa nitori iwọde ‘June 12’ l’Akurẹ
Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Gbogbo awọn ọlọja lo ti gbogbo ṣọọbu wọn pa latari iwọde ‘June 12’…
Ko sohun to le yẹ ẹ, iwọde ‘June 12’ yoo waye-Ẹgbẹ Akẹkọọ
Ẹgbẹ awọn akẹkọọ agbegbe Guusu ilẹ Naijiria, pataki ju lọ ilẹ Yoruba, ti ni ikede ti…
‘June 12’ : Ẹ rin sibi to ba wu yin, a ti pese aabo -Ileeṣẹ ọlọpaa Kwara
Ibrahim Alagunmu, Ilorin Ileeṣẹ ọlọpaa, ẹka ti ipinlẹ Kwara, ti kede pe awọn ti pese aabo…
Maaluu ni Faruq ati Jobo ji gbe tọwọ fi tẹ wọn ni Kwara
Ibrahim Alagunmu, Ilọrin Ẹsọ alaabo (NSCDC) ẹka ti ipinlẹ Kwara ti mu Issa Faruq ati Jobo…
Akin gbe ọrẹbinrin rẹ lọ sile Kabiru, lẹyin to fipa ba a lo pọ tan ni wọn ge e si wẹwẹ l’Apomu
Florence Babaṣọla Ọwọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ọṣun ti tẹ Kabiru Ayedun, ẹni ọdun mọkandinlogoji, lori ẹsun…
Lẹyin ti wọn ge ẹya ara Hassana tan ni wọn ju iyooku ara ẹ sẹgbẹẹ ọna ni Kwara
Ibrahim Alagunmu, Ilorin Ọdọmọbinrin kan torukọ rẹ n jẹ Hassana Muhammad, ni awọn afurasi oloogun owo…
Olukọ meji, akẹkọọ mẹjọ, lawọn agbebọn tun ji gbe nileewe kan ni Kaduna
Faith Adebọla Ibẹrubojo tun ti gbode kan niluu Zaria, pẹlu bawọn janduku agbebọn kan ṣe ya…