Dorcas fomi gbigbona bo ọkọ ẹ lara bii ṣaki ni Meiran, o lo n gbe nnkan gbẹyin oun

Faith Adebọla Titi di asiko ta a fi n ko iroyin yii jọ, ọsibitu ni baale…

Eyi lawọn oṣere ilẹ wa tiku mu lọ laarin wa lọdun yii

Florence Babaṣọla Oniruuru iṣẹlẹ a-gbọ-sọgbanu to ṣẹlẹ kaakiri orileede Naijiria ninu ọdun 2023 yii ko yọ…

Owo wọgbo: Ọmọ Naijiria yii fẹnu kọ niluu Oyinbo, ni wọn ba sọ ọ sẹwọn

Adewale Adeoye Iwaju Onidaajọ Ọgbẹni William Wood, tile-ẹjọ giga kan to wa lagbegbe Perth Sheriff, lorile-ede Scotland, ni wọn…

Ibinu buruku ti gbe Adebayọ de  ọgba ẹwọn Kirikiri, ọrẹ rẹ lo gun pa

Adewale Adeoye Iwaju Onidaajọ Balogun, tile-ẹjọ Majisireeti kan to wa niluu Yaba, nipinlẹ Eko, ni wọn…

Ẹyin tẹ ẹ n ra waini, ẹ fura o: NAFDAC tun ṣawari ibi ti wọn ti n pọn ayederu waini, eeyan mẹwaa lọwọ tẹ 

Ibrahim Alagunmu, Ilọrin Afi ki gbogbo awọn ti wọn ba fẹẹ ra awọn ohun mimu, paapaa…

Ajalu buruku! Alaga kansu ku lasiko to n ki awọn Onigbagbọ kiri lọjọ ọdun Keresi l’Ejigbo

Florence Babaṣọla, Oṣogbo Lasiko ti awọn eeyan n ṣe ajọyọ, ti wọn si n ṣe pọpọṣinṣin…

Ọwọ ọlọpaa ti tẹ Emmanuel, panẹẹli ina solar lo lọọ ji tu 

Ibrahim Alagunmu Akolo ileeṣẹ ọlọpaa ẹka tipinlẹ Eko, ni afurasi adigunjale kan, Emmanuel Achogwu, ẹni ọgbọn…

Iya yii fẹẹ farugbo ara ṣẹwọn, egboogi oloro loun at’ọmọ ẹ n ta l’Ekoo

Faith Adebọla Geeti ọgba ẹwọn ti n ṣẹwọ wẹlẹwẹlẹ si mama arugbo ẹni aadọrin ọdun kan, Sẹlifat…

Baba agbalagba yii yoo pẹ lẹwọn o, ọrọ fisa ilu oyinbo lo fi n lu awọn eeyan ni jibiti l’Akurẹ

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Ile-ẹjọ Majisireeti kan to fikalẹ siluu Akurẹ, ti ni ki baba agbalagba kan,…

Lawal ji mọto ọga ẹ gbe l’Ekoo, lo ba lọọ ta a fun wọn n’llọrin

Ibrahim Alagunmu, Ilọrin Akolo ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Kwara ni Ọgbẹni Lawal Sulyman, ti wọn fẹsun kan…

Ọwọ ọlọpaa tẹ ikọ adigunjale ẹlẹni marun-un to n yọ awọn araalu lẹnu

Adewale Adeoye Ọdọ awọn alaṣẹ ileeṣẹ ọlọpaa agbegbe Kurmi, nijọba ibilẹ Bakori, nipinlẹ Katsina, lawọn ikọ adigunjale ẹlẹni marun-un kan ti wọn maa n…