Awọn ọlọpaa ṣi n wa Roselyn at’alejo ẹ tawọn kan ji gbe l’Ọfada

Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Titi ta a fi pari akojọpọ iroyin yii ni awọn ọlọpaa ipinlẹ Ogun…

Ẹgbẹrun marundinlọgọta naira la maa san fun oṣiṣẹ to kere ju lọ l’Ekoo – Sanwo-Olu

Faith Adebọla, Eko Atẹwọ ayọ rẹpẹtẹ lo rọjo lọjọ Abamẹta, Satide yii, nibi ayẹyẹ ayajọ awọn…

Afẹnifẹre ṣayẹyẹ aadọrin ọdun ifilọlẹ ẹgbẹ wọn l’Akurẹ

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Ọgọọrọ eeyan ni wọn pejọ sinu ijọ Anglican Dafidi mimọ to wa lagbegbe…

Muhammed, ọmọ Fulani, to n da awọn eeyan lọna labule Agbagi ti bọ sọwọ ọlọpaa

Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Muhammed Altine lorukọ ọkunrin pupa yii, ọkan ninu awọn Fulani to maa n…

Ṣẹgun ra ọkada lọwọ ẹni to pade lẹwọn, lo ba loun ko mọ pe ẹru ole ni

Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta    Bo tilẹ jẹ pe ọkunrin kan, Ṣẹgun Ṣofẹla, to pe ara ẹ ni…

 Lẹyin oṣu meji ti wọn ko ọpọ apo irẹsi lọ ni Bodija, awọn aṣọbode tun fọ ṣọọbu awọn onirẹsi l’Ọja Ọba

Ọlawale Ajao, Ibadan Lai tii to oṣu meji ti wọn jalẹkun ṣọọbu awọn onirẹsi lọja Bodija,…

Oṣere tiata, Lizzy Anjọrin, bimọ tuntun s’Amẹrika

Jide Alabi Idunnu ti ṣubu layọ fun ọkan ninu awọn oṣere ilẹ wa, Lizzy Anjọrin, pẹlu…

A ti sin awọn Fulani mejilelogoji ta a ko l’Okitipupa jade nipinlẹ Ondo- Adelẹyẹ

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Alakooso ẹsọ Amọtẹkun nipinlẹ Ondo, Oloye Adetunji Adelẹyẹ, ni awọn ti da awọn…

Lọọya Baba Ijẹṣa ti sọrọ o, o ni oṣere naa ati Princess ti jọ ṣe wọle-wọde ri

Sinima ere ori itage ni wahala to n lọ laarin oṣere ori itage ilẹ wa ti…

Aarọ kutu ni Ogunnaike lọọ digun ja oni POS lole, lọlọpaa ba mu un l’Abẹokuta

 Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Bi Rafiat Wahab, ọmọbinrin kan to ni ṣọọbu ti wọn ti n fowo…

A ṣi n ṣakojọpọ iwa itapa-sofin tawọn to n beere Orilẹ-ede Yoruba hu l’Abẹokuta- Oyeyẹmi

Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Alukoro ọlọpaa nipinlẹ Ogun, DSP Abimbọla Oyeyẹmi, ti sọ pe ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ…