Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Muhammed Altine lorukọ ọkunrin pupa yii, ọkan ninu awọn Fulani to maa n…
Ṣẹgun ra ọkada lọwọ ẹni to pade lẹwọn, lo ba loun ko mọ pe ẹru ole ni
Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Bo tilẹ jẹ pe ọkunrin kan, Ṣẹgun Ṣofẹla, to pe ara ẹ ni…
Lẹyin oṣu meji ti wọn ko ọpọ apo irẹsi lọ ni Bodija, awọn aṣọbode tun fọ ṣọọbu awọn onirẹsi l’Ọja Ọba
Ọlawale Ajao, Ibadan Lai tii to oṣu meji ti wọn jalẹkun ṣọọbu awọn onirẹsi lọja Bodija,…
Oṣere tiata, Lizzy Anjọrin, bimọ tuntun s’Amẹrika
Jide Alabi Idunnu ti ṣubu layọ fun ọkan ninu awọn oṣere ilẹ wa, Lizzy Anjọrin, pẹlu…
A ti sin awọn Fulani mejilelogoji ta a ko l’Okitipupa jade nipinlẹ Ondo- Adelẹyẹ
Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Alakooso ẹsọ Amọtẹkun nipinlẹ Ondo, Oloye Adetunji Adelẹyẹ, ni awọn ti da awọn…
Lọọya Baba Ijẹṣa ti sọrọ o, o ni oṣere naa ati Princess ti jọ ṣe wọle-wọde ri
Sinima ere ori itage ni wahala to n lọ laarin oṣere ori itage ilẹ wa ti…
Aarọ kutu ni Ogunnaike lọọ digun ja oni POS lole, lọlọpaa ba mu un l’Abẹokuta
Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Bi Rafiat Wahab, ọmọbinrin kan to ni ṣọọbu ti wọn ti n fowo…
A ṣi n ṣakojọpọ iwa itapa-sofin tawọn to n beere Orilẹ-ede Yoruba hu l’Abẹokuta- Oyeyẹmi
Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Alukoro ọlọpaa nipinlẹ Ogun, DSP Abimbọla Oyeyẹmi, ti sọ pe ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ…
Iru ki waa leleyii, ọkada meji fori sọ tirela l’Abẹokuta, lo ba tẹ wọn pa
Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Ni nnkan bii aago mẹjọ kọja iṣẹju mẹẹẹdọgbọn alẹ ọjọ Ẹti, ọgbọnjọ, oṣu…
Olori Ijo Ansarudeen, Shehu Ahmad, yoo ba gbogbo Musulumi aye sọrọ loni-in o
Nitori bi nnkan ṣe n lọ ni Naijiria wa loni-in yii, ati nitori asiko ti a…
Nibi ti Kelechukwu atọrẹ ẹ ti fẹẹ lu mọtọ ti wọn ji gbe ta ni gbanjo lọwọ ti tẹ wọn l’Ekoo
Faith Adebọla, Eko Ọrẹ lawọn mejeeji pe ara wọn, Kelechukwu Nnonyelu ati Godspower Okongi, ṣugbọn ọrẹ…