Muhammed, ọmọ Fulani, to n da awọn eeyan lọna labule Agbagi ti bọ sọwọ ọlọpaa

Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Muhammed Altine lorukọ ọkunrin pupa yii, ọkan ninu awọn Fulani to maa n…

Ṣẹgun ra ọkada lọwọ ẹni to pade lẹwọn, lo ba loun ko mọ pe ẹru ole ni

Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta    Bo tilẹ jẹ pe ọkunrin kan, Ṣẹgun Ṣofẹla, to pe ara ẹ ni…

 Lẹyin oṣu meji ti wọn ko ọpọ apo irẹsi lọ ni Bodija, awọn aṣọbode tun fọ ṣọọbu awọn onirẹsi l’Ọja Ọba

Ọlawale Ajao, Ibadan Lai tii to oṣu meji ti wọn jalẹkun ṣọọbu awọn onirẹsi lọja Bodija,…

Oṣere tiata, Lizzy Anjọrin, bimọ tuntun s’Amẹrika

Jide Alabi Idunnu ti ṣubu layọ fun ọkan ninu awọn oṣere ilẹ wa, Lizzy Anjọrin, pẹlu…

A ti sin awọn Fulani mejilelogoji ta a ko l’Okitipupa jade nipinlẹ Ondo- Adelẹyẹ

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Alakooso ẹsọ Amọtẹkun nipinlẹ Ondo, Oloye Adetunji Adelẹyẹ, ni awọn ti da awọn…

Lọọya Baba Ijẹṣa ti sọrọ o, o ni oṣere naa ati Princess ti jọ ṣe wọle-wọde ri

Sinima ere ori itage ni wahala to n lọ laarin oṣere ori itage ilẹ wa ti…

Aarọ kutu ni Ogunnaike lọọ digun ja oni POS lole, lọlọpaa ba mu un l’Abẹokuta

 Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Bi Rafiat Wahab, ọmọbinrin kan to ni ṣọọbu ti wọn ti n fowo…

A ṣi n ṣakojọpọ iwa itapa-sofin tawọn to n beere Orilẹ-ede Yoruba hu l’Abẹokuta- Oyeyẹmi

Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Alukoro ọlọpaa nipinlẹ Ogun, DSP Abimbọla Oyeyẹmi, ti sọ pe ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ…

Iru ki waa leleyii, ọkada meji fori sọ tirela l’Abẹokuta, lo ba tẹ wọn pa

Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Ni nnkan bii aago mẹjọ kọja iṣẹju mẹẹẹdọgbọn alẹ ọjọ Ẹti, ọgbọnjọ, oṣu…

Olori Ijo Ansarudeen, Shehu Ahmad, yoo ba gbogbo Musulumi aye sọrọ loni-in o

Nitori bi nnkan ṣe n lọ ni Naijiria wa loni-in yii, ati nitori asiko ti a…

Nibi ti Kelechukwu atọrẹ ẹ ti fẹẹ lu mọtọ ti wọn ji gbe ta ni gbanjo lọwọ ti tẹ wọn l’Ekoo

Faith Adebọla, Eko Ọrẹ lawọn mejeeji pe ara wọn, Kelechukwu Nnonyelu ati Godspower Okongi, ṣugbọn ọrẹ…