Nitori igbakeji gomina, awọn aṣofin kọju ija sira wọn l’Ondo

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Wahala to n ṣẹlẹ nile igbimọ aṣofin ipinlẹ Ondo gbọna mi-in yọ laaarọ…

Ileeṣẹ aṣọbode mu kẹkẹ maruwa atọkọ bọọsi awọn fayawọ

Stephen Ajagbe, Ilọrin Ileeṣẹ aṣọbode ilẹ yii, ẹka tipinlẹ Kwara, ti ṣafihan awọn kẹkẹ maruwa kan pẹlu…

Awọn to ni ibaṣepọ pẹlu Logun ti wa ni iyasọtọ – Ijọba Kwara

Stephen Ajagbe, Ilọrin Ijọba ipinlẹ Kwara ti kede pe gbogbo awọn to ni ibaṣepọ pẹlu Aminu…

Koronafairairọọsi pa Aminu Logun, olori oṣiṣẹ lọfiisi gomina Kwara

Stephen Ajagbe, Ilorin Ijọba ipinlẹ Kwara ti fidi ẹ mulẹ pe arun Koronafairọọsi lo pa Aminu…

O maa ṣe o! Olori oṣiṣẹ lọfiisi gomina Kwara ti ku o

Stephen Ajagbe, Ilorin Iroyin kan to tẹ wa lọwọ sọ pe Alhaji Aminu Logun ti i…

Lẹyin ti Wasiu tẹwọn de lo tun lọọ ja ọkada gba n’Ipokia

Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Bi iṣẹ kan ba wa ti ọmọkunrin kan, Wasiu Raji, fẹran lati maa…

Eyi ni bawọn aṣofin Ondo ṣe fẹẹ yọ igbakeji gomina

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Lonii, ọjọ Iṣẹgun,lawọn ọmọ ile igbimọ aṣofin bẹrẹ igbesẹ yiyọ Ọnarebu Agboọla Ajayi…

Baba mi lo nifẹẹ si iṣẹ ṣọja, nitori tiwọn ni mo ṣe wa nileewe naa bayii – Lọọya Kunle

Ọdọmọde ni, nitori ọjọ ori rẹ ko ju mẹẹẹdọgbọn(25), lọ. Ṣugbọn iṣẹ adẹrin-in-poṣonu to n ṣe…

Awọn aṣofin Eko buwọ lu atunṣe eto iṣuna

Faith Adebọla, Eko Ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Eko ti ṣagbeyẹwo aba eto iṣuna ipinlẹ naa lakọtun,…

Kayeefi nla! Niluu Ifọn, ara san pa maaluu meje

Fun igba akọkọ niluu Ifọn Ọṣun, maaluu meje ni ara nla to san lasiko ojo nla…

Ondo: Oluwatuyi di akọwe ijọba, bẹẹ ni Ọtẹtubi yoo di kọmiṣanna laipẹ

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ  Gomina Rotimi Akeredolu tipinlẹ Ondo ti yan akọwe ijọba tuntun, Temitayọ Oluwatuyi. Eyi…