Eemọ lukutu pẹbẹ! Baba fọmọ bibi inu ẹ loyun, o lọmọ naa n da oun lọrun ni

Faith Adebọla, Ogun Adajọ nikan lo le mọ iru sẹria toun yoo da fun baale ile…

Ajagun-fẹyinti Ọladipupọ Diya ti ku o

Faith Adebọla Igbakeji olori orileede wa tẹlẹri, to tun jẹ alakooso gbogbo awọn ọmoogun ori ilẹ…

Wọn ba oku oludije sipo gomina Labour Party ninu yara ẹ l’Ekoo

Monisọla Saka Ọkan ninu awọn oludije dupo gomina ninu ibo abẹle ti yoo waye nipinlẹ Imo…

Awọn agbebọn pa pasitọ, wọn tun jiyawo ẹ gbe lọ

Monisọla Saka Ojiṣẹ Ọlọrun kan, Rẹfurẹndi Musa Mairimi, ti i ṣe alaamojuto ijọ ECWA, agbegbe Buda…

Lara fẹnsi ile tawọn mẹrin kan duro si lọkọ elepo kan tẹ wọn pa si l’Abẹokuta   

Faith Adebọla, Abẹokuta Eeyan mẹrin ni ajọ ẹṣọ oju popo ilẹ wa fidi rẹ mulẹ pe…

Nitori ọmọ rẹ to ku sọsibitu wọn, baale ile kan lu nọọsi daku l’Akurẹ

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Titi di asiko yii lawọn ọlọpaa ṣi n wa ọkunrin awakọ kan ti…

EFCC ya bo Akurẹ, wọn fi pampẹ ofin gbe awọn oni POS ọgọrin

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Bii ọgọrin awọn oni POS ni ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ…

O ma ṣe o! Oṣere tiata Yoruba ku lojiji

 Jọkẹ Amọri Loootọ ni aisan to lagbara da oṣere ilẹ wa kan, Akingbemisọla Dorcas Anjọla, gbalẹ…

Wọn ni Wolii Salami mọ nipa iyawo ile to ku sinu ṣọọsi rẹ n’Idanre

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Wolii ijọ alaṣọ funfun kan to wa niluu Alade-Idanre, nijọba ibilẹ Idanre, Salami…

Eko lawọn mẹrin yii n gbe, Ijẹbu ni wọn ti n lọọ digunjale lojoojumọ

Faith Adebọla Beeyan ba ri awọn afurasi mẹrin wọnyi lagbegbe Mushin, nijọba Ibilẹ Oṣodi-Isọlọ, nipinlẹ Eko,…

Awọn araalu fẹhonu han l’Ọgbẹsẹ, wọn lawọn ajinigbe ko jẹ ki awọn sinmi

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Ọgọọrọ awọn eeyan ni wọn jade niluu Ọgbẹsẹ, n’ijọba ibilẹ Ariwa Akurẹ, laaarọ…