Monisọla Saka Lati mu ki irọrun de ba awọn araalu, paapaa ju lọ awọn oṣiṣẹ ijọba,…
Aarẹ Tinubu ko lẹtọọ lati yan olori le awọn aṣofin lọwọ -Ẹgbẹ agba Hausa
Adewale Adeoye Ẹgbẹ agba ẹya Hausa kan ti wọn n pe ni ‘Northern Elders Forum’ (NEF)…
Ẹgbẹ ọmọ Ekiti kilọ fun Fayẹmi: Da ogun biliọnu owo ilu to o ko jẹ pada
Monisọla Saka Ẹgbẹ awọn ọmọ bibi ilu Ekiti kan, Ekiti Patriotic Consultative Forum (EPCF), ti gba…
Oṣere tiata tun bimọ fun Portable olorin zah zuu
Monisọla Saka Ọkunrin olorin hip hop tawọn ọdọ isinyii n ko jẹ nigboro, Habeeb Okikiọla ọmọ…
O ma ṣe o, akẹkọọ fasiti yii ku lẹyin to pari idanwo aṣekagba rẹ
Adewale Adeoye Titi di akoko ta a n ko iroyin yii jọ, inu ọfọ nla gbaa…
Awọn ṣọja ṣawari ileeṣẹ ti wọn ti n ta ọmọ tuntun, ọpọlọpọ aboyun ni wọn ko kuro nibẹ
Monisọla Saka Ọwọ palaba awọn amookunṣika ẹda ti ṣegi pẹlu bi awọn ọmọ ogun ilẹ Naijiria,…
Adajọ ju Ariyibi sẹwọn ọdun marun-un, kokeeni lo gbe
Adewale Adeoye Ni bayii, adajọ ile-ẹjọ giga kan niluu Eko, Onidaajọ Chukwuejekwu Aneke, ti ni ki…
Emi gan-an fara mọ yiyọ owo iranwọ epo bẹntiroolu, ṣugbọn… Peter Obi
Adewale Adeoye Oludije dupo aarẹ orileede yii lẹgbẹ oṣelu ‘Labour Party’ (LP), Ọgbẹni Peter Obi, ti…
Ko sohun to le da orileede Biafra duro-Nnamdi Kanu
Adewale Adeoye Olori ẹgbẹ ajijangbara kan ti wọn n pe ni ‘Indigenous People Of Biafra’ (IPOB),…
Awọn aṣofin fontẹ lu u pe ki Aarẹ Tinubu yan olubadamọran ogun
Adewale Adeoye Awọn ọmọ ileegbimọ aṣofin agba orileede yii ti fontẹ lu u pe ki Olori…
Wọn ka eegun oku mọ awọn gende mẹrin lọwọ
Adewale Adeoye Ileeṣẹ ọlọpaa agbegbe Bagadaza, nijọba ibilẹ Dukku, nipinlẹ Gombe, ti sọ pe ọwọ awọn…