Jamiu Abayọmi Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko, labẹ idari CP Idowu Owohunwa, ti paṣẹ lẹyẹ ọ sọka…
Ọmọ ọdun mejila ti wọn ji ifun inu rẹ lasko iṣẹ abẹ ti ku
Monisọla Saka Ọmọdekunrin ọmọ ọdun mejila kan, Adebọla Akin-Bright, ti wọn ni ko si ifun kekere…
Iya Mohbad ko yẹ lẹni teeyan n ba kẹdun, ki i ṣe abiyamọ gidi-Lere Ọlayinka
Jamiu Abayomi Latari bi gbogbo eeyan ṣe n ba iya ọdọmọde olorin taka-sufee ilẹ wa nni,…
Eto idibo to daa ju ninu itan orileede yii nijọba Buhari ṣe lọdun – Adeṣina
Florence Babaṣọla, Oṣogbo Oludamọran pataki fun Aarẹ tẹlẹ lorileede yii, Mohammadu Buhari, Fẹmi Adeṣina, ti sọ…
Ọlọpaa ti mu nọọsi to gun Mohbad labẹrẹ ko too ku
Adewale Adeoye Gbajumọ oṣerebirin ilẹ wa nni, Iyabo Ojo, ti fidi rẹ mulẹ pe awọn ọlọpaa ipinlẹ Eko ti fọwọ ofin mu nọọsi to gun Oloogbe Ilerioluwa…
Awọn Dokita fẹẹ ṣe iwọde lori ọkan ninu wọn to ku sẹnu iṣẹ l’Ekoo
Jamiu Abayọmi Ẹgbẹ awọn dokita, ileewosan olukọni ti ipinlẹ Eko, Lagos University Teaching Hospital (LAUTH-ARD), ti…
Ijọba ti hu oku Mohbad olorin fun ayẹwo
Jamiu Abayọmi Ni ibamu pẹlu aṣẹ ti Gomina ipinlẹ Eko, Babajide Sanwoolu, ati ileeṣẹ ọlọpaa, labẹ…
Gbogbo eeyan ẹ gba mi o, emi kọ ni Sam Larry ti wọn n wa o-AY
Monisọla Saka Ọrọ Yoruba to sọ pe meji leeyan maa n rin ti fẹẹ di wahala…
O ṣẹlẹ! Tiribuna yọ gomina Kano nipo, wọn ni APC lo wọle
Faith Adebọla Igbimọ onidaajọ to n gbọ awuyewuye to ba su yọ ninu eto idibo sipo…
O ṣẹlẹ, adajọ to n gbọ ẹjọ Ta-ni-Ọlọrun pariwo: Ẹ maa ṣaagun si mi o
Ibrahim Alagunmu, Ilọrin Ṣe lawọn eeyan n rẹrin-in arintakiti nile-ẹjọ Upper Area, niluu Ilọrin, nibi ti…
Wọn ti tun ko ọpọlọpọ awọn ọmọ Naijiria ti wọn ha si Libya wale
Monisọla Saka Ko din ni aadọjọ ati marun-un (155) awọn ọmọ Naijiria ti wọn ti ha,…