Ọrẹoluwa Adedeji Eeyan mẹsan-an, ninu eyi ti ọkunrin agbalagba mẹrin, obinrin mẹta atawọn ọmọ kekere meji,…
Arinrin-ajo mọkanla jona ku sinu ijamba ọkọ l’Ọrẹ
Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Poroporo lomije n da loju awọn eeyan ti wọn wa nibi ijamba ọkọ…
Atubọtan kootu: Awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu PDP fẹhonu han l’Ọṣun
Florence Babaṣọla, Oṣogbo Latari bi ile-ẹjọ to n gbọ ẹsun to ṣu yọ ninu ibo gomina…
Ọmọọdun mọkandinlogun lọọ fọ ṣọọṣi ati ile meji n’Ilaro
Faith Adebọla, Ogun Ọjọ-ori ọmọkunrin ti wọn porukọ ẹ ni Abiọdun Elegbede yii ko ti i…
Jẹnẹretọ kootu ni Fọlọrunṣọ fẹẹ ji gba tọwọ fi ba a Ado-Odo
Faith Adebọla Yooba bọ, wọn ni Fọlọrunṣọ kan o gbọdọ fokun ọgẹdẹ gun ọpẹ, amọ ọrọ…
Ọkọ agboworin to wọle Tinubu nijọsi ṣina wọbẹ ni, ko si sowo ninu ẹ- Akọwe APC
Monisọla Saka Akọwe awọn igbimọ to n ṣeto ipolongo ibo atawọn eto mi-in ninu ẹgbẹ oṣelu…
Eyi lawọn eeyan tijọba Buhari tori ẹ paarọ owo ilẹ wa
Ọrẹoluwa Adedeji Pẹlu bi awọn araalu ṣe n to rẹrẹẹrẹ lawọn banki kaakiri ilẹ wa lati…
Ile akọku ni Yisa ko awọn ọmọ ọdun meje, marun-un lọ, to si fipa ba wọn lo pọ
Florence Babaṣọla, Oṣogbo Ọwọ ẹṣọ Amọtẹkun ipinlẹ Ọṣun ti tẹ ọmọkunrin ẹni ọdun mejilelọgbọn kan, Yisa, lori ẹsun pe o…
Ọmọọdun mọkandinlogun lọọ fọ ṣọọṣi ati ile meji n’Ilaro
Gbenga Amos, Abẹokuta Ọjọ-ori ọmọkunrin ti wọn porukọ ẹ ni Abiọdun Elegbede yii ko ti i…
Ibo Ọṣun: Ile-ẹjọ Ko-tẹ-mi-lọrun yoo gba ẹtọ wa pada fun wa-Adeleke
Florence Babaṣọla, Oṣogbo Gomina ipinlẹ Ọṣun, Ademọla Adeleke, ti sọ pe idajọ ti ko lẹsẹ nilẹ…
Ibo Ọṣun: Oyetọla jawe olubori ni kootu
Florence Babaṣọla, Oṣogbo Igbimọ to n gbọ ẹsun to ṣuyọ ninu idibi gomina to waye nipinlẹ…