Ẹ lọọ so ewe agbejẹẹ m’ọwọ, ki i ṣe Naijiria nikan lo n koju iṣoro- Minisita Tinubu

Adewale adeoye Minisita fun ọrọ awọn ọdọ lorileede yii, Dọkita Jamila Ibrahim, ti rọ awọn eeyan orileede yii, paapaa ju lọ awọn ọdọ ti wọn n gbaradi silẹ bayii…

Ẹ lẹtọọ labẹ ofin lati ṣewọde ita gbangba, ṣugbọn ẹ ma fi ba dukia ijọba jẹ-Ijọba Eko

Adewale adeoye Ọkan pataki lara ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC nipinlẹ Eko, to tun jẹ Akọwe funjọba ipinlẹ naa, Abilekọ Abimbọla Salu-Hundeyin, ni awọn…

A ti mọ awọn ọbayejẹ to wa nidii iwọde tawọn araalu fẹẹ ṣe-Ileeṣẹ ọtẹlẹmuyẹ

Adewale adeoye Birọ ni, bi ootọ ni, ko sẹnikan to mọ, ṣugbọn ileeṣẹ ọlọpaa ọtẹlẹmuyẹ (DSS) orileede yii lawọn ti mọ awọn ọbayejẹ ẹda ti wọn…

Nitori iwọde to n bọ,  ọga ọlọpaa ni ki wọn maa ko aloku taya kaakiri ṣọọbu awọn fọganaisa

Adewale adeoye Pẹlu bi ọjọ tawọn araalu lawọn fẹẹ ṣewọde ita gbangba ṣe n sun mọ etile bayii, ọga agba ọlọpaa patapata…

Loootọ ni mo ṣewọde ita gbangba ri, ṣugbọn ki i ṣe eyi to mu wahala dani – Tinubu

Adewale Adeoye Olori orileede yii, Aarẹ Bọla Ahmed Tinubu, ti sọju abẹ nikoo pe loootọ loun…

Ali Ndume ti sọrọ o: Ko sẹni to le le mi ninu ẹgbẹ APC, a jọ da a silẹ ni

Adewale adeoye Senatọ Ali Ndume, to n ṣoju ẹkun Borno-South, nipinlẹ Borno, ti ni lọwọ yii, ojulowo ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC loun, toun ko…

Awọn ọlọja  fariga fun ọmọ Tinubu, wọn ni aaye ohun to ṣe l’Ekoo ko si l’Edo

Adewale Adeoye Orin, ‘ohun to o le gba, ma fi lọ ẹda ẹgbẹ rẹ’ ni agbarijọpọ awọn ọlọja kan nipinlẹ Edo…

Peter Obi sọ fun Ọnanuga: Tọrọ aforiji ko si sanwo itanran, aijẹ bẹẹ…

Faith Adebọla Gomina ipinlẹ Anambra nigba kan, to tun jẹ ondije-dupo aarẹ labẹ ẹgbẹ oṣelu Labour…

Ẹgbẹ APC ṣewọde l’Ekiti wọn ni alaga wọn ko palietiifu jẹ

Taofeeq Surdiq, Ado-Ekiti Lọjọ Iṣẹgun, Tusidee, ọjọ kẹtalelogun, oṣu yii, lawọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu APC nipinlẹ…

Wahala l’Ararọmi Owu, araalu lawọn ko fẹ ọba to wa nipo, lawọn janduku ba dana sun aafin

Florence Babaṣọla, Oṣogbo Ara ko rọ okun, bẹẹ ni ko rọ adiyẹ bayii niluu Ararọmi Owu,…

A ko ni i boju wẹyin lori iwọde yii, Abuja ni yoo si ti bẹrẹ- Ṣoworẹ

Faith Adebọla Oludije funpo aarẹ ninu eto idibo gbogbogboo ọdun to kọja, to tun jẹ ilumọ-ọn-ka…