Gbenga Amos, Abẹokuta Gbogbo ẹni to ba moju oludije sipo gomina lorukọ ẹgbẹ APC, Aṣiwaju Bọla…
Category: Ìròyìn
Iwọde awọn ọdọ n’Ibadan ṣakoba fun ipolongo ibo Peter Obi ati Ṣeyi Makinde
Ọlawale Ajao, Ibadan Iwọde ti awọn ọdọ n ṣe kaakiri ilu Ibadan, nitori iṣoro ọwọngogo owo…
Iwọde lori owo tuntun: Ṣọja yinbọn pa ọlọkada n’Ibadan
Faith Adebọla Iwọde ati ifẹhonuhan to n waye niluu Ibadan, ipinlẹ Ọyọ, latari inira ti pipaarọ…
ICPC fi panpẹ ofin gbe manija banki tawọn ọmọọṣẹ rẹ n fọna jibiti kowo sinu ẹrọ ATM
Monisọla Saka Ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ atawọn ẹsun mi-in to jẹ mọ ọn lorileede Naijiria (ICPC),…
Ijiya nla n duro de awọn to n ta owo Naira atawọn to n lo o nilokulo-Emefiele
Monisọla Saka Bi awọn banki ilẹ wa ba tẹle aṣẹ ti olori banki apapọ ilẹ wa,…
Wọn ka ayederu owo Naira tuntun mọ Joseph atọrẹ ẹ lọwọ nileepo
Faith Adebọla Pẹlu bawọn eeyan o ṣe fi bẹẹ ri owo tuntun gba, debi ti wọn…
Nitori wahala owo tuntun, epo bẹntiroolu: Ọba Ọgọmbọ rawọ ẹbẹ sijọba Buhari
Ọrẹoluwa Adedeji Ọba Muslim Abiọdun Ogunbọ, Ogudu Ọṣhadi ti ilu Ọgọmbọ, nijọba ibilẹ Eti-Ọsa, nipinlẹ Eko,…
Ọwọngogo owo tuntun: Awọn gomina APC rawọ ẹbẹ si Buhari
Faith Adebọla Lojuna ati wa ojutuu si wahala owongogo owo Naira tuntun to gbode kan lasiko…
Awọn agbebọn pa adajọ sinu kootu to ti n gbọ ẹjọ lọwọ
Monisọla Saka Ọjọ buruku eṣu gbomi mu ni Ọjọbọ, Tọsidee, ọjọ keji, oṣu Keji, ọdun yii,…
Nitori wahala owo Naira tuntun, Oluwoo sọko ọrọ si olori banki apapọ ilẹ wa
Florence Babaṣọla, Oṣogbo Oluwoo ti ilu Iwo, Ọba Abdulrosheed Adewale Akanbi, ti bu ẹnu atẹ lu…
Awọn ọdọ fẹhonu han n’Ibadan nitori owo Naira ati epo bẹntiroolu, wọn ba dukia rẹpẹtẹ jẹ
Ọlawale Ajao, Ibadan Nitori bi nnkan ko ṣe fara rọ lorileede yii, tawon araalu ko rowo…