Mẹjọ ninu awọn ọmọ ẹgbẹ akọrin ti wọn ji gbe ti gba itusilẹ

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Mẹjọ lara awọn ọmọ ẹgbẹ akọrin CAC, Oke-Igan, niluu Akurẹ, tawọn agbebọn kan…

Ero mẹrinla lo kun inu bọọsi yii lasiko to jona gburugburu lori ere

Faith Adebọla Ta a ba yọwo ti iṣẹ Ọlọrun Ọba to pọ, ati bawọn agba ṣe…

Ọmọ ọdun mẹtala yii ti rẹwọn he, ole lo lọọ ja  l’Akurẹ  

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Kootu to n gbọ ẹjọ awọn ọmọde, eyi to wa ninu ọgba Oke-Ẹda,…

Iru ki waa leleyii, wọn ba oku ọga to ni otẹẹli Water View, ninu yara kan n’llọrin 

Ibrahim Alagunmu, Ilọrin Titi di asiko ta a n ko iroyin yii jọ, ko ti i…

Wolii fun ọmọ Mohbad ni miliọnu mẹwaa Naira

Jamiu Abayọmi Iranṣẹ Ọlọrun kan, Wọlii Jeremiah Omoto Fufeyin, to jẹ oludasilẹ ati adari ijọ Christ…

Sam Larry ti sọrọ: Eyi lohun to faja laarin emi ati  Mohbad 

Jamiu Abayọmi Samson Balogun Eletu, ti ọpọ tun mọ si Sam Larry, ọmọkunrin toun naa maa…

Nitori tiyen loun ko le fẹ ẹ, Amẹẹdi yinbọn pa Nuura, o tun para ẹ

Ọlawale Ajao, Ibadan Kayeefi kan ṣẹlẹ l’Ọjọruu, Wẹsidee, ọjọ kẹtadinlọgbọn (27), oṣu Kẹsan-an, ọdun yii, nigba…

Gomina Adeleke fagi le ayẹyẹ ayajọ ominira l’Ọṣun 

Florence Babaṣọla, Oṣogbo Gomina Ademọla Adeleke ti sọ pe ko ni i si ayẹyẹ kankan lati…

Ọkunrin yii ma daju o, ẹ wo ohun to bo mọlẹ laaye

Monisọla Saka Ọwọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Anambra ti tẹ ọkunrin kan, Ifeanyi Ezenwankwo, nitori iya buruku…

Ọba ti wọn ko ba fi Ifa ati iṣẹṣe yan ko le laṣẹ lẹnu-Oloye Fatoki

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Aarẹ ẹgbẹ Igbelarugẹ Aṣa ati Iṣe Yoruba lagbaaye, Oloye Adebayọ Fatoki, ti darapọ…

Awọn agbebọn ji awọn ọmọ ẹgbẹ akọrin CAC mẹẹẹdọgbọn gbe n’Ifọn

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Awọn agbebọn ti tun ṣọṣẹ lọsan-an ọjọ Ẹti, Furaidee, ọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu Kẹsan-an…