Ki laa ti waa ṣeyi si, adajọ ni ki wọn lọọ fi Olori Naomi ati Oriyọmi Hamzat pamọ sọgba ẹwọn

Monisọla Saka Asiko yii ki i ṣe eyi to daa rara fun arẹwa obinrin to tun…

Ileepo MRS dowo pọ pẹlu ileefọpo Dangote lati maa ta epo ni ẹdinwo kaakiri Naijiria

 Monisọla Saka Ileeṣẹ ifọpo Dangote, iyẹn Dangote Refinery, ti kede pe awọn ti ni ajọsọ ọrọ…

Ibi ayẹyẹ igbeyawo lawọn kan ti n bọ ti wọn fi ji marun-un ninu wọn gbe ni Kwara 

Ibrahim Alagunmu, Ilọrin  Inu idaamu ati iporuuru ọkan ni awọn eeyan Agboolé Igbẹdẹ, niluu Odó-Ọwá, nijọba…

Ko sohun ti ẹnikẹni le ṣe si i, atunto owo-ori tuntun maa waye dandan ni- Tinubu

Adewale Adeoye ‘Ba a ba ju abẹbẹ soke nigba igba, ibi pẹlẹbẹ kan naa lo maa…

Ko sorileede kan lagbaaye ti ko si talaka nibẹ, kaluku n dọgbọn si i ni – Tinubu 

Adewale adeoye ‘Ko sibi ti iṣe ko si, ko sorileede kankan lagbaaye lasiko yii, titi kan…

Ile-ẹjọ ti gba beeli Farotimi, eyi lawọn ohun to gbọdọ ṣe

Surdiq Taofeek, Ado-Ekiti   Fọfọọfọ ni ile-ẹjọ Majisireeti kan niluu Ado-Ekiti, nipinlẹ Ekiti, nibi ti igbẹjọ…

Nitori ohun to ṣẹlẹ n’Ibadan, Hamzat Oriyọmi dero ileewosan

Ọrẹoluwa Adedeji Ba a ti n sọ yii, ileewosan kan ti wọn ko darukọ ni Oludasilẹ…

A maa too fọ ipinle Ogun mọ, ọmọ ẹgbẹ okunkun meje lọwọ ti tẹ bayii- Ọmọlọla 

Adewale adeoye Meje lara awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun Aye kan ti wọn n da omi alaafia…

Awọn ọlọpaa ti mu Olori Ṣilẹkunọla Naomi, iyawo Ọọni tẹlẹ

Jọkẹ Amọri Asiko yii ki i ṣe eyi to daa rara fun arẹwa Olori Ọọni Ileefẹ…

Ajọ eleto idibo orileede Benin ṣabẹwo silẹ wa, eyi lohun to gbe wọn wa

Adewale adeoye Awọn aṣoju ajọ eleto idibo orileede Benin Commission Electoral Nationale Autonomie’ (CENA) ti de…

Ogunṣua gboṣuba fawọn ọmọ Mọdakẹkẹ, o rọ wọn lati mu idagbasoke ilu ni pataki

 Florence Babaṣọla, Oṣogbo Ogunṣua ti ilu Mọdakẹkẹ, Ọba Joseph Olubiyi Toriọla, ti ke si gbogbo awọn…