Jọkẹ Amọri Gomina ipinlẹ Sokoto, to tun jẹ ọkan ninu awọn oludije sipo aarẹ lẹgbẹ oṣelu PDP, ti sọ pe oun ti juwọ silẹ fun Alaaji Atiku Abubakar toun naa n dije fun ipo yii kan naa. Ni papa iṣere MKO Abiọla, niluu Abuja, nibi ti eto idibo naa ti …
Read More »Wọn tẹ eeyan mọkanlelọgbọn pa lasiko ti wọn fẹẹ lọọ gba ounjẹ ati ẹbun ọfẹ ni Port Harcourt
Ọrẹoluwa Adedeji Eeyan bii mọkanlelọgbọn lawọn ọlọpaa sọ pe o ti pade iku ojiji ni ṣọọṣi kan ti wọn n pe ni King’s Assembly, Port Harcourt, nipinlẹ Rivers, lasiko ti wọn fẹẹ lọọ gba ounjẹ atawọn nnkan mi-in ti ijọ Ọlọrun naa fẹẹ fun awọn eeyan to ku diẹ kaato …
Read More »Oṣere tiata yii pariwo: Ẹ gba mi o, latọjọ ti mo ti ṣojọọbi mi ni itẹkuu lawọn oku ti n yọ mi lẹnu
Monisọla Saka Kayeefi! Inu iboji larakunrin yii ti ṣe ọjọ ibi ẹ. Oṣerekunrin ilẹ Ghana kan to ṣayẹyẹ ọjọ ibi rẹ ni itẹ oku laipẹ yii ti pariwo pe awọn isinku ọrun n yọ oun lẹnu. Ọlọjọ ibi ọhun torukọ ẹ n jẹ Nkrumah Samuel, ti pupọ awọn eniyan n …
Read More »2023: Ẹgbẹ TOTT rọ Tinubu atawọn oludije yooku lati panu pọ gbe Ọṣinbajo kalẹ
Ọrẹoluwa Adedeji Ẹgbẹ kan, The Ọsinbajo Think Tank (TOTT), ti parọwa si aṣaaju ẹgbẹ oṣelu APC, Bọla Tinubu ati awọn oludije yooku funpo aarẹ orileede yii lati panu pọ ṣatilẹyin fun Igbakeji Aarẹ, Ọjọgbọn Yẹmi Ọṣinbajo, lati gbe apoti ibo lorukọ ẹgbẹ APCl ọdun 2023. Ninu atẹjade kan ti ẹgbẹ …
Read More »Ọwọ tẹ afurasi mẹta lori ọkunrin agbẹ kan ti wọn pa nibudo iwakusa l’Ọṣun
Florence Babaṣọla, Oṣogbo Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ọṣun ti mu eeyan mẹta ti wọn jẹ oṣiṣẹ nibudo iwakusa kan lori iku to pa ọkunrin agbẹ kan lagbegbe Ibẹrẹkodo, nijọba ibilẹ Ila-Oorun Atakumọsa, nipinlẹ Ọṣun. Oloogbe naa, ẹni ti wọn pe orukọ rẹ ni Ajewọle, ni wọn sọ pe o ku lẹyin …
Read More »Ibo abẹlẹ APC Ọyọ: Fọlarin jawe olubori, Adelabu gba ẹgbẹ SDP lọ
Ọlawale Ajao, Ibadan Sẹnetọ Teslim Fọlarin lo jawe olubori ninu idibo abẹle ẹgbẹ oṣelu All Progresives Congress, APC. Fọlarin, ẹni to n ṣoju ẹkun idibo Aarin-Gbungbun ipinlẹ Ọyọ nileegbimọ aṣofin agba niluu Abuja lọwọlọwọ, lo la alatako rẹ to sun mọ ọn ju lọ ninu idije naa mọle pẹlu ibo …
Read More »Awọn eleyii n gbowo ipa lọwọ awọn onimọto, wọn loṣiṣẹ ijọba Eko lawọn
Faith Adebọla, Eko Ọrẹ timọtimọ ni awọn ọkunrin mẹrin yii, Taiwo Falọdun, ẹni ọdun mejidinlaaadọta, Adedire Ọlaniyi, ẹni ọdun mejilelogoji, Fẹmi Ọṣunkọya, ẹni ọdun mẹtalelaaadọta ati Ọlawale Edu, ẹni ọdun mọkanlelaaadọta, ṣugbọn rikiṣi lo pa wọn pọ ti wọn fi dọrẹ, iṣẹẹbi ti wọn fẹsun ẹ kan wọn ni pe …
Read More »Nitori burẹdi ọgọrun-un Naira, Fulani ṣa Jamiu ladaa pa ni Kwara
Ibrahim Alagunmu, Ilọrin Ile-ẹjọ Majisreeti kan to fi ilu Ilọrin ṣe ibujokoo ti paṣẹ pe ki wọn sọ Fulani kan, Alaaji Haruna Adu, si ọgba ẹwọn Oke-Kura, niluu Ilọrin, fẹsun pe o ṣa Jamiu Sọliu to n ta burẹdi ladaa pa niluu Kanbi, nijọba ibilẹ Moro, nipinlẹ naa, nitori burẹdi …
Read More »INEC fi ọjọ mẹfa kun ọjọ idibo abẹle awọn ẹgbẹ oṣelu ilẹ wa
Ọrẹoluwa Adedeji Ajọ eleto idibo ilẹ wa ti fi ọjọ mẹfa kan kun gbedeke ọjọ ti wọn fun awọn ẹgbẹ oṣelu kaakiri ilẹ wa lati ṣeto idibo abẹle wọn, ki wọn si fa oludije kalẹ. Lọjọ Ẹti, Furaidee, opin ọsẹ yii, ni wọn sọ eyi di mimọ lẹyin arọwa ti …
Read More »Wọn ti tu Oriyọmi Hamzat silẹ lahaamọ
Iroyin to tẹ ALAROYE lọwọ ni pe awọn ọlọpaa ti tu Oludasilẹ Redio Agidigbo, Oriyọmi Hamzat ti wọn gbe lọ si akata wọn silẹ. Ninu atejade kan to tẹ ALAROYE lọwọ, eyi ti Adebayọ Yousuph Grey, fọwọ si lorukọ awọn alaṣẹ ileeṣẹ naa ni wọn ti sọ pe ‘‘Wọn ti …
Read More »Ibo Abẹle PDP: Awọn tọọgi lu ọlọpaa, oniroyin atawọn alatako Makinde
Ọlawale Ajao, Ibadan Ọpọlọpọ ọlọpaa ati oniroyin lo fara pa nibi idibo abẹle ẹgbẹ oṣelu People’s Democratic Party (PDP), to waye ni papa iṣere Lekan Salami, laduugbo Adamasingba, n’Ibadan, l’Ọjọruu, Wẹsidee, ọsẹ yii. Awọn ọlọpaa lo na oniroyin, iyẹn, Yinka Adeniran, to jẹ akọroyin fun The Nation, nigba ti iya …
Read More »