Bi wọn ba n tan Oyetọla, koun naa ma tan ara rẹ o jare

Ko si ohun to jẹ tuntun ninu ki awọn kan jokoo sibi kan ki wọn maa…

Atiku ṣa fẹẹ fọwọ ara ẹ ṣera ẹ ṣaa

Ayọdele Fayọṣe, ọkan pataki ninu awọn aṣaaju ẹgbẹ oṣelu PDP sin Atiku Abubakar ni gbẹrẹ ipakọ,…

Awọn aṣofin wa naa o wulo, tara wọn nikan ni wọn n ṣe

Aṣọfin kan, Sẹnetọ Ndume, lo sọrọ kan, ọrọ naa yoo si da bii isọkusọ loju awọn…

Loootọ, loootọ, o yẹ ki olori awọn EFCC yii ṣẹwọn!

 Nigba ti Adajo Chizoba Oji dajọ pe ki awọn ọlọpaa tete mu olori awọn EFCC, Abdul…

Awọn ajinigbe ọna Eko s’Ibadan, Makinde ṣeun

O Ṣoju Mi Koro! Nigba miiran, ẹjọ ati atotonu ki i mu nnkan ya, bi ọrọ…

Ọrọ ti Sanwoolu sọ fawọn agbofinro yii, ọrọ gidi ni o

Ni ọsẹ to kọja yii, Gomina Babajide Sanwoolu ipinlẹ Eko ranṣẹ si gbogbo ọlọpaa ati awọn…

‘Ẹ ma ma jẹ kawọn Fulani ajinigbe sọ ilẹ Yoruba dahoro’

Nigba ti wọn ji awọn eeyan gbe lọna Ibadan lọsẹ to lọ lọhun-un, ti wọn gbe…

Ibi ti ẹ ba yọ si Afẹnifẹre yii ko daa!

Lati igba ti awọn eeyan pataki pataki ilẹ Yoruba kan ti lọ sọdọ Baba Reuben Faṣọranti…

O ṣoju mi koro (Apa Kin-in-ni)

Naijiria ki i ṣe ti Fulani, wọn n tan ara wọn jẹ lasan ni NIgbakigba ti wọn ba…

Ṣebi ẹyin naa n gbọ isọkusọ lẹnu ọkunrin-kukuru-biliisi

O ṣoju mi koro (Apa Kin-in-ni)   Bo ba jẹ gbogbo awọn gomina lo ri bii…

Wahala ọna Eko s’Ibadan, nibo ni Faṣọla wa o

Wahala ọna Eko s’Ibadan, nibo ni Faṣọla wa o Awọn kinni kan wa ti wọn fi…