Loootọ, loootọ, o yẹ ki olori awọn EFCC yii ṣẹwọn!

 Nigba ti Adajo Chizoba Oji dajọ pe ki awọn ọlọpaa tete mu olori awọn EFCC, Abdul…

Awọn ajinigbe ọna Eko s’Ibadan, Makinde ṣeun

O Ṣoju Mi Koro! Nigba miiran, ẹjọ ati atotonu ki i mu nnkan ya, bi ọrọ…

Ko sẹni to koriira Tinubu, oun ni ko yẹra ẹ wo

Ọrọ to kun ẹnu awọn ti wọn n tẹle Aṣiwaju Bọla Tinubu ni pe Yoruba ko…

 Ẹfun abi eedi, ọmọ ọdun mẹrindinlogun fipa ba iyawo ẹgbọn ẹ sun l’Ondo

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Ọmọkunrin ẹni ọdun mẹrindinlogun kan tórúkọ rẹ n jẹ Precious lo ti wa…

Eyi ni bi ọkọ iya wa ṣe da bẹntiroolu si wa lara, to ṣana si i, to si pa mẹrin ninu wa

Francis Iyiade Awọn meji to ku ninu awọn ọmọ marun-un ti ọkọ iya wọn, iyẹn Ojo…

Ọwọ tẹ awọn ọmọ ‘Yahoo’ mẹrin to fi Aminat ṣoogun owo ni Ṣagamu

Gbenga Amos, Ogun   Yoruba bọ, wọn lọmọ ẹni ku san ju ọmọ ẹni sọnu lọ,…

Lẹyin ibo 2023, a o ni i gburoo APC mọ – Atiku

Monisọla Saka Oludije dupo aarẹ lẹgbẹ oṣelu PDP, Alaaji Atiku Abubakar, ti sọko ọrọ si ẹgbẹ…

Ile-ẹjọ ni ìjọba Ọṣun ko gbọdọ yan Olufọn tuntun

Florence Babaṣọla, Oṣogbo Ile-ẹjọ giga ijọba ipinlẹ Ọṣun kan to fikalẹ siluu Oṣogbo ti paṣẹ pe…

Nitori awọn ajinigbe ati adigunjale, awọn agbaagba Yoruba fẹẹ ṣepade nla n’Ibadan

Nitori bi awọn ajinigbe ṣe n pitu lọtun-un, ti awọn adigunjale n ṣoro losi lojoojumọ, ajọ…

O ma ṣe, o eeyan mọkanla jona ku nipinlẹ Kogi

Monisọla Saka Ko sẹni to maa ri bi ọpọ eeyan ṣe jona ku, ti awọn ọkọ…

Ẹgbẹ PDP Ọṣun pariwo: Gbogbo ọkọ ijọba lawọn Oyetọla ti pin mọra wọn lọwọ o

Florence Babaṣọla, Oṣogbo Ẹgbẹ oṣelu PDP nipinlẹ Ọṣun ti ke si Gomina Adegboyega Oyetọla pe ko…