Hafsat tọju ọmọ ẹ pamọ, o ni wọn ji i gbe ni, lo ba n beere owo itusilẹ lọwọ ọkọ atijọ to bi i fun

Monisọla Saka Ọwọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Kano, ti tẹ obinrin ẹni ọdun marundinlọgbọn (25) kan, Rahma…

Mo ti dariji gbogbo awọn to ṣẹ mi-Adeleke

Florence Babaṣọla, Oṣogbo Gomina ipinlẹ Ọṣun, Ademọla Adeleke, ti sọ pe oun ti fi tọkantọkan dariji…

Fungba diẹ ni ifasẹyin to de ba wa, Oyetọla fọkan awọn ọmọ ẹgbẹ APC Ọṣun balẹ

Florence Babaṣọla, Oṣogbo Gomina ana nipinlẹ Ọṣun, Alhaji Adegboyega Oyetọla, ti ke si awọn ọmọ ẹgbẹ…

Aṣọ ọlọpaa ati ti ṣọja lawọn agbebọn yii n wọn fi ṣọṣẹ

Monisọla Saka Awọn agbebọn ti wọn n da awọn araalu, kaakiri ipinlẹ Anambra laamu ti tun…

Ijọba ti ile-epo marundinlọgọrin pa l’Ọṣun

Adewale Adeoye Ni bayii, ẹka ileeṣẹ to n ri sọrọ tita epo bẹntiroolu nilẹ wa, ‘Nigeria…

Atiku balẹ si kootu  ti wọn ti n gb’ẹjọ to pe ta ko Tinubu l’Abuja

Adewale Adeoye Ṣe lẹsẹ ko gbero rara ni kootu kan ti wọn ti n gbọ ẹjọ…

Ẹ woju minisita ilẹ wa yii, biliọnu mejilelogun lo ko jẹ

Adewale Adeoye Ajọ to n gbogun ti iwa ibajẹ ati  ṣiṣe owo ilu mọku-mọku lorileede yii,…

Lẹyin idajọ ile-ẹjọ to ga ju lọ: Ijo, ilu at’orin lawọn oṣiṣẹ fi ki Adeleke kaabọ s’ọfiisi l’Ọṣun 

Florence Babaṣọla, Oṣogbo Tilu-tifọn lawọn oṣiṣẹ ijọba ipinlẹ Ọṣun fi ki Gomina Ademọla Adeleke kaabọ si…

Baale ile ki ọmọọdọ ti wọn gba sile mọlẹ, o ṣẹ ‘kinni’ fun un karakara

Monisọla Saka Lọjọ Iṣẹgun, Tusidee, ọjọ kẹsan-an, oṣu Karun-un, ọdun yii, ni ile-ẹjọ Majisireeti to wa…

Igbẹjọ idibo aarẹ: Ẹyin adajọ, ẹ ma gba riba, idajọ to ni ibẹru Ọlọrun ni kẹ ẹ ṣe-Primate Ayọdele

Monisọla Saka Primate Elijah Ayọdele ti i ṣe oludasilẹ ati olori ijọ INRI Evangelical Spiritual Church,…

Ẹrọ BIVAS yii lo maa ṣẹ awọn oloṣelu oniwayo lẹyin-Atiku

Faith Adebọla Oludije funpo aarẹ labẹ asia ẹgbẹ oṣelu Peoples Democratic Party (PDP), ninu eto idibo…