Asiko yii ki i ṣe eyi to dara fun gbajumọ oṣere ilẹ wa to tun n…
Author: admin
Awọn eeyan fẹhonu han niluu Ọrẹ lori ọwọngogo epo ati owo Naira tuntun
Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Ọgọọrọ awọn ọdọ ni wọn tu jade niluu Ọrẹ, nijọba ibilẹ Odigbo, laaarọ…
Ile-ẹjọ ṣekilọ: Buhari ati CBN ko gbọ fi kun ọjọ ti wọn yoo fi paarọ owo atijọ mọ
Faith Adebọla K’eku ile gbọ ko sọ fun toko o, ki adan gbọ ko si lọọ…
Nitori ifẹhonu han ti wọn fẹẹ ṣe lori ọrọ ọwọngogo epo, awọn ọlọpaa pe ipade pajawiri l’Ondo
Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Kọmiṣanna ọlọpaa ipinlẹ Ondo, Oyeniran Oyeyẹmi, ti sare pe ipade pajawiri latari ifẹhonu han tawọn kan…
Nitori bi nnnkan ṣe ri nita, Portable olorin pin ounjẹ fawọn eeyan
Jọkẹ Amọri Bo tilẹ jẹ pe ọpọ ni ko fẹran imura ati awọn iwa kan to…
Iku n rọ dẹdẹ lori ọmọ Naijiria yii o, egboogi oloro lo gbe tọwọ ọlọpaa fi tẹ ẹ ni India tẹ ẹ
Monisọla Saka Ọmọ orilẹ-ede Naijiria kan, Charles Diffodile, ti ko si panpẹ awọn ọlọpaa ilẹ India…
Lori owo Naira tuntun, awọn gomina APC mẹta wọ Buhari rele-ẹjọ
Faith Adebọla Gbọnmi-si-i-omi-o-to-o to n waye latari ipaarọ owo Naira atijọ si tuntun to n lọ…
Ile akọku ni Ismaila tan ọmọọleewe kan lọ to ti fipa ba a lo pọ n’Ilọrin
Ibrahim Alagunmu, Ilọrin Ile-ẹjọ Magistreeti kan to fi ilu Ilọrin ṣe ibujokoo ti paṣẹ pe ki…
Wọn ka agbari eeyan mọ Abdulrahman lọwọ, o lẹgbẹẹ titi loun ti ri i
Faith Adebọla Ọrọ ti o jọra wọn ni afurasi ọdaran ẹni ọdun mejidinlọgbọn kan n sọ…
‘Bi banki ilẹ wa ba fi le sun ọjọ owo atijọ gbigba siwaju, a ko ni i kopa ninu eto idibo’
Jọkẹ Amọri Mẹtala ninu awọn alaga ẹgbẹ oṣelu mejidinlogun ta a ni nilẹ yii ni wọn…
Ile-ẹjọ to ga ju lọ da Lawan lare, wọn loun loludije funpo sẹnetọ tawọn faṣẹ si
Faith Adebọla Ilẹkẹ ma ja sile, ma ja sita, ibi kan nilẹkẹ maa ja si, beeyan…