Ibrahim Alagunmu, Ilọrin Ni nnkan bii aago kan ku iṣẹju mẹẹẹdogun Gomina ipinlẹ Kwara AbdulRahman AbdulRazaq,…
Author: admin
O ma ṣe o, igbakeji gomina to ṣẹṣẹ fipo silẹ ku lojiji
Surdiq Taofeek, Ado-Ekiti Lẹyin aisan ranpẹ ti wọn lo ṣe e, Igbakeji gomina ipinlẹ Ekiti, labẹ…
Wọn mu alaga kansu pẹlu ayederu iwe idibo, maggi, owo atawọn nnkan mi-in
Jọkẹ Amọri Alaga ijọba ibilẹ Obi, nipinlẹ Nasarawa, Joshua Zheyekpuwudu, yoo rojọ, ẹnu rẹ yoo fẹrẹ…
Ere lemi n ṣe, mi o dunkooko m’awọn Igbo o-MC Oluọmọ
Faith Adebọla, Eko Bi wọn ba n sọ pe “Owuyẹ, aṣoro-i-sọ-bii-ọrọ” ati pe ‘ẹyin lohun, bo…
Idibo ileegbimọ aṣofin bẹrẹ l’Ọṣun, ṣugbọn awọn araalu ko fi bẹẹ jade
Florence Babaṣọla, Oṣogbo Yatọ si bo ṣe ṣẹlẹ lasiko ibo aarẹ to waye kọja, awọn oludibo…
Daniel fi ọmọ bibi inu ẹ ṣe baranda, eeyan mẹta ọtọọtọ lo ta a fun l’Ogun
Faith Adebọla Boya aṣa buruku kan ti Portable gbajugbaju onkọrin hipọọpu zahzuu zeeh da ninu awo…
Ọwọ tẹ mama agbalagba pẹlu ayederu nnkan eelo idibo l’Ekoo
Faith Adebọla Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Eko, SP Benjamin Hundeyin, lọwọ awọn ti tẹ mama agbalagba…
Ibo ku ọjọ kan, wọn ji oludije sipo igbakeji gomina gbe
Faith Adebọla Ka kẹru, ka kẹru wale lọdẹ n ba lọ soju ogun, ọna nikẹta n…
Ọmọ ẹgbẹ okunkun ni Kẹhinde, o tun n digunjale, ọsibitu ti wọn ṣẹṣẹ kọ ni wọn lọọ fọ n’Ipẹru
Faith Adebọla Afaimọ lawọn afurasi ọdaran mẹta tọwọ tẹ yii ko ni i pẹ lẹwọn bii…
Ori ko oludije gomina ipinlẹ Ọyọ yọ lọwọ awọn agbanipa
Ọlawale Ajao, Ibadan Ẹlẹkọ ọrun polowo iku lọ sile Sẹnetọ Teslim Fọlarin, oludije funpo gomina lorukọ…
Nitori ti wọn ni ko ma luyawo ẹ pa, Ogunwusi gun araale rẹ lọbẹ pa l’Ado-Ekiti
Taofeek Surdiq, Ado-Ekiti Okunrin ẹni ọdun mejilelogun kan, Fẹmi Ogunwusi, nikan lo le ṣalaye iru inu…