Awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun paayan mẹta, wọn gbe oku wọn sa lọ l’Ọwọ

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Eeyan mẹta ni wọn pade iku ojiji niluu Ọwọ, ti i ṣe ibujokoo…

Idajọ kootu: Tinubu, Oyetọla ki Adeleke ku oriire

Florence Babaṣọla, Oṣogbo Aarẹ tuntun ti wọn ṣẹṣẹ dibo yan lorileede Naijiria, Aṣiwaju Bọla Ahmed Tinubu,…

Oṣelu ti kọja bayii, ka fọwọsowọpọ fun idagbasoke Ọṣun lo ku – Gomina Adeleke

Florence Babaṣọla, Oṣogbo Gomina ipinlẹ Ọṣun, Sẹnetọ Ademọla Adeleke, ti ke si gbogbo awọn eeyan ipinlẹ…

Gomina Makinde ko gbọdọ ti i fi ẹnikẹni jẹ Alaafin lasiko yii-Idile ọmọọba Ọyọ 

Ọlawale Ajao, Ibadan Awọn idile ọba Alaafin Ọyọ mẹsan-an ti rawọ ẹbẹ si Gomina ipinlẹ Ọyọ,…

Ẹwọn n run nimu Quadri yii o, Qudus lo gun lọbẹ pa l’Ekoo

Faith Adebọla, Eko Ọdọmọkunrin kan ti wọn porukọ ẹ ni Quadri Raji Arẹmu, ti ko ara…

Ọlọpaa gba eeyan mejilelogun silẹ lọwọ ajinigbe

Faith Adebọla Iku ti iba pa ni, bo ba ṣi ni ni fila, o yẹ ka…

Biliọnu mẹrinla Naira ni wọn yoo fi tun Aso Rock ṣe silẹ de Tinubu

Monisọla Saka Ni ipalẹmọ fun ayẹyẹ eto iburawọle fun aarẹ tuntun ti wọn ṣẹṣẹ dibo yan…

Ẹfun abeedi! Abdulwahab fibinu lu ọmọ rẹ pa nitori ọka-baba

 Adewale Adeoye Awọn alaṣe ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Kano ti sọ pe awọn ti gbọ si iṣẹlẹ…

Ọmọ ẹgbẹ okunkun mẹta fiku ṣefa jẹ, ọlọpaa ni wọn doju ija kọ

Adewale Adeoye Ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Rivers, ti sọ pe mẹta lara awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun kan…

Ijọba Eko bẹrẹ ayẹwo fawọn to n lọ silẹ Mẹka

Adewale Adeoye Bi gbogbo nnkan ba lọ bo ṣe yẹ, ọjọ Aje. Monde, ọjọ kẹjọ, oṣu…

Mi o fẹẹ ri awon to n gbe egboogi oloro ati ọmọ ẹgbẹ okunkun mọ nipinlẹ Ogun-Abiọdun

Faith Adebọla Bi asiko kan ba wa ti Ọmọọba Gomina ipinlẹ Ogun koro oju gidigidi, ti…