EFCC ti mu minisita Buhari, biliọnu rẹpẹtẹ ni wọn lo ko jẹ

Monisọla Saka Ajọ to n gbogun ti ajẹbanu ati ṣiṣe owo ilu mọkumọku lorilẹ-ede wa,  Economic…

Iyawo mi n yan ale, ko tun fi mi lọkan balẹ, mo fẹẹ kọ ọ-Shuaibu 

Ibrahim Alagunmu, Ilọrin Lẹyin ti baale ile kan, Shuaibu Ọba, tu gbogbo aṣiri iwa buruku ọwọ…

Wọn ti mu Sunday, aṣọ ṣọja lo fi n lu jibiti n’llọrin 

Ibrahim Alagunmu, Ilọrin Akolo ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Kwara ni ọkunrin kan, Sunday Gbemis, ẹni ọdun mẹrinlelogoji,…

Idi ti mo fi ṣedasilẹ ‘Alternative High School’ fawọn ọmọbinrin l’Ọṣun -Rẹmi Tinubu

Florence Babaṣọla, Oṣogbo Aya aarẹ orileede yii, Arabinrin Olurẹmi Tinubu, ti sọ pe itara ti oun…

Eyi ni bi Sẹnetọ Olurẹmi Tinubu ṣe gba mi lọwọ awọn oniroyin to fẹẹ maa fi mi pawo – Adeleke

Florence Babaṣọla, Oṣogbo Gomina ipinlẹ Ọṣun, Sẹnetọ Ademọla Adeleke, ti ṣapejuwe aya aarẹ orileede yii, Sẹnetọ…

Ẹgbẹ oniṣẹṣe kilọ fawọn ọdọ: Itanjẹ lasan ni, ko si nnkan to n jẹ oogun-owo ninu Ifa

Florence Babaṣọla, Oṣogbo Pẹlu bi ọpọ awọn ọdọ orileede yii ṣe n fi ẹmi ara wọn…

Ṣẹyin naa ti gbọ ohun to ṣẹlẹ si Fathia Balogun

Monisọla Saka Asiko yii ki i ṣe eyi to dara rara fun ọkan ni awọn gbajumọ…

Ẹwọn n run nimu ọkunrin to n ṣe piọ wọta yii o, inu kanga lo ti n pọn’mi to n rọ sinu ọra

Taofeek Surdiq, Ado-Ekiti Ọwọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ekiti ti tẹ ọkunrin ẹni aadọta ọdun kan, Ọgbẹni…

A maa bẹrẹ si i ṣe ayẹwo ọpọlọ fawọn arufin oju popo ka a too pe wọn lẹjọ – Ijọba Eko

Monisọla Saka Ijọba ipinlẹ Eko ti ni gbogbo arufin ojupopo ti ọwọ ba ti tẹ lati…

Ijọba Kwara ti bo awọn ẹran maaluu to jẹ majele tawọn alapata kan fẹẹ maa ta faraalu mọlẹ 

Ibrahim Alagunmu, Ilọrin Wọn ni ohun ti a o ba fẹ ko bajẹ, oju ni a…

Tinubu tun fẹẹ yawo lọwọ Banki Agbaye

Faith Adebọla Minisita fun eto iṣuna-owo nilẹ wa, Ọgbẹni Wale Ẹdun, ni gbogbo eto ti pari,…