Awọn ajijagbara ‘Yoruba Nation’ fipa gbakoso redio Amuludun, n’Ibadan, ọlọpaa ti mu ninu wọn

Ọlawale Ajao, Ibadan Lẹyin ti wọn ti wọn ko awọn oṣiṣẹ ileeṣẹ redio Amuludun, n’Ibadan, ni…

Ko si Aarẹ to ṣe daadaa fawọn araalu to Buhari -Ganduje

Adewale Adeoye Gomina ipinlẹ Kano, Alhaji Abdullahi Ganduje, ti sọ pe ko si ani-ani kankan nibẹ rara…

Aarẹ Buhari ko ṣatilẹyin kankan fun ẹgbẹ wa-Miyetti Allah

Aarẹ Buhari ko ṣatilẹyin kankan fun ẹgbẹ-Miyetti Allah Adewale Adeoye Ẹgbẹ awọn Fulani daran-daran, ‘Coalition Of…

Ijọba apapọ kede ọjọ Aje gẹgẹ bii isinmi lẹnu iṣẹ

Adewale Adeoye Bi ohun gbogbo ba lọ bo ṣe yẹ, ọjọ Aje, Mọnde, ọjọ kọkandinlọgbọn, oṣu, Karun-un, ọdun…

Awọn agbẹjoro mi yoo tu aṣiri eru to wa lasiko ibo aarẹ-Atiku

Adewale Adeoye ‘Pe ile–ejọ to ga ju lọ lorileede yii,  Supreme Court, da ẹjọ ti mo pe lori Alhaji…

O ma ṣe o, lẹyin ti Samuel f’owo ile-iwe rẹ ati tọrẹ ẹ ta tẹtẹ, lo binu para ẹ

Ismail Adeẹyọ Boya owe afago kẹyin aparo, ohun oju n wa loju n ri lọrọ akẹkọọ…

Ẹ faaye gba awọn ọmọ Naijiria to fẹẹ kawe pẹlu awọn ẹbi wọn – Ẹgbẹ akẹkọọ.

Monisọla Saka Ẹgbẹ awọn akẹkọọ lorilẹ-ede Naijiria, National Association of Nigerian Students (NANS), ti ke si…

Awọn eeyan ilu Iwo ti ko mi si gbese – Oluwoo

Florence Babaṣọla, Oṣogbo Oluwoo ti ilẹ Iwo, Ọba Adewale Akanbi, ti sọ pe ohun ki i na…

Wọn foju mi ri mabo latimọle ọlopaa-Ṣeun Kuti

Adewale Adeoye Gbajumọ olorin Afrobeat nni, Ṣeun Kuti, tawọn ọlọpaa orileede wa fọwọ ofin mu lori ẹsun pe…

Mi o jẹ Murphy Afọlabi lowo ko too ku, wọn parọ mọ mi ni – Adunni Ade

Monisọla Saka Arẹwa oṣere tiata ilẹ wa, ṣugbọn ti wọn bi nilẹ Amẹrika, Adunni Adewale, tọpọ eeyan…

Aisha Buhari beere fun ajẹmọnu ati owo ifẹyinti fawọn iyawo aarẹ

Monisọla Saka Iyawo Aarẹ orilẹ-ede wa to n palẹmọ ati kogba sile, Aisha Buhari, ti gbẹnu…