Iyawo mi fẹẹ fi lilu pa mi o, mi o fẹ ẹ mọ- Gbade 

Ọlawale Ajao, Ibadan “Loootọ ni mo fọ ọkọ mi leti. Oniṣekuṣe ọkunrin ni, ọmọ kan bayii…

Gomina Dapọ Abiọdun gbesẹ lori ofin konilegbele opin ọsẹ l’Ogun

Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Oni ọjọ Ẹti, Furaidee, ọjọ kẹrinla, oṣu kẹjọ, ni ijọba fopin si konilegbele…

Tọmọde-tagba lo n ṣedaro Dapọ Williams, ọmọ Yoruba daadaa to ku si London

Ilu oyinbo nibẹ lo n gbe, ni London. Ṣugbọn ki i ṣe pe o n gbebẹ…

O ma ṣe o, o ku oṣu meji pere ki ọmọbinrin yii ṣeyawo ni mọto pa a lori ọkada

Faith Adebọla Ibanujẹ ti dori agba kodo fawọn mọlẹbi ọmọbinrin arẹwa ti ẹ n wo fotọ…

Awọn adigunjale to yinbọn pa oṣiṣẹ ileepo Akurẹ d’ero ile-ẹjọ

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Meji ninu awọn adigunjale to yinbọn pa oṣiṣẹ ileepo kan lọjọ kẹtalelogun oṣu…

Ẹ wo Bọọda Tiṣa, o ti rẹwọn he o, ọmọ ọdun mẹwaa lo fipa ba sun l’Akurẹ

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Tiṣa kan ti wọn porukọ rẹ ni Ọmọtayọ Adanlawọ ti gba idajọ ẹwọn…

Adeṣọla Ọlaniyan gbade, o di ọba ilu Ipokia tuntun

Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Ọjọbọ, Wẹsidee, ọsẹ yii, ni Gomina ipinlẹ Ogun, Ọmọọba Dapọ Abiọdun, fun Onipokia…

Ẹ je ka bẹ Pasitọ Adeboye atawọn olori ẹlẹsin to ku, ki wọn ma ba aṣa Yoruba jẹ o

Ọjọgbọn agbaye kan, Purofẹsọ Toyin Falọla, ti sọ pe gbogbo ẹni yoowu to ba fẹran aṣa…

Adajọ ti gba beeli awakọ to pa Tolulọpẹ Arotile

Lẹyin ti ile-ẹjọ gba beeli ọmọkunrin to wa mọto, ati ẹni to ni mọto to pa…

Baba ọgọrin ọdun to fipa ba ọmọ ọdun marun-un lo pọ l’Agege loun fẹẹ fẹ ẹ ni

 Faith Adebọla Tika-tẹgbin lawọn eeyan n wo baba ẹni ọgọrin ọdun kan, Ebenezer Ọlaiya Oyewọle, nigba…

Adedeji, ayederu lọọya, n lọ sẹwọn ọdun mẹta ba a ṣe kọwe rẹ l’Abẹokuta

Adefunkẹ Adebiyi,Abẹokuta  Kootu ko fi ẹjọ ayederu lọọya kan, Adedeji Ebenezer, ẹni ti aṣiri ẹ tu…