Fidio: Awọn ṣọja lo ṣatilẹyin dáwọn Hausa ti wọn fi jo ile ati ṣọobu awọn Yoruba

Baálẹ̀ Ṣàṣà, Oloye Akinlade Àjàní ti sọ pe ko si ootọ́ ninu ọrọ ti Seriki Ṣàṣà n gbe kiri pe awọn làwọn da ọja Sasa silẹ. Baba naa ni ọ̀rọ̀ to jinna soootọ ni. O fi kun un pe awọn ṣọja lo ṣatileyin fawon Hausa ti wọn fi jo ile ati ṣọọbu awọn Yoruba.

Leave a Reply