Laarin ọsẹ mẹta, obinrin mẹrin bimọ fun kafinta yii, o logoji ọmọ loun fẹẹ bi

Nura Walwala lorukọ ọkunrin to duro laarin awọn obinrin mẹrin yii, ẹni ọdun mẹrindinlogoji ni, oun…

Ọmọbinrin yii pokunso, nitori ti wọn lo ji pata

Bi ẹ ti n wo ọmọbinrin daadaa yii, ko si laye mọ. Ọgbọnjọ, oṣu kin-in-ni, ọdun 2021…

Ọọni loun ko binu si Sunday Igboho mọ, oun ko si ni i sọrọ lori ohun to ṣe

Ki awueywye to gbode kan le dohun igbagbe patapata lori bi Oloye Sunday Igboho ṣe fẹnu…

Ijọba ti ko awọn ti Fulani ṣa ladaa n’Ibarapa lọ sileewosan UCH, n’Ibadan

Faith Adebọla Ọjọ kẹrin lẹyin ti Gomina ipinlẹ Ọyọ, Ṣeyi Makinde, ṣeleri lati mojuto awọn ti…

Arun Korona tun pa eeyan marun-un l’Ekoo

Faith Adebọla  Arun Koronafairọọsi to ti di ẹrujẹjẹ kari aye bayii ti tun da ẹmi eeyan…

Awọn eeyan binu si ọmọ Wasiu Ayinde to n bu Sunday Igboho

Aderohunmu Kazeem Pelu ibinu lawọn eeyan fi n ṣepe le ọmọ Alaaji Wasiu Ayinde, Arabinrin Damilọla…

Buhari fi awọn olori ologun ilẹ wa to yọ nipo ṣe Ambasadọ

Ọjọbọ, Tọsidee, ọsẹ yii, ni Aarẹ ilẹ wa, Muhammadu Buhari kede awọn olori ileeṣẹ ologun to…

Aarẹ Buhari ti fi oṣu mẹta kun asiko ọga ọlọpaa patapata, Muhammed Adamu

Aare Muhammadu Buhari ti fi oṣu mẹta mi-in kun asiko ọga ọlọpaa patapata fun ilẹ wa,…

Ọlọpaa n wa awọn to fibọn gba ogun miliọnu lọwọ awọn oṣiṣẹ ijọba Ekiti

Oluyinka Soyemi, Ado-Ekiti Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ekiti ti bẹrẹ iwadii lori iṣẹlẹ idigunjale kan to waye…

Nitori aabọ owo-osu t’Akeredolu n san fawọn oṣiṣẹ, awọn dokita bẹrẹ iyansẹlodi l’Ondo 

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Ẹgbẹ awọn dokita to n ṣiṣẹ nileewosan ijọba nipinlẹ Ondo ti bẹrẹ iyansẹlodi…

Ẹgbẹ akẹkọọ ijinlẹ ede Yoruba ṣayẹyẹ ọdun aṣa ni Kwara

Stephen Ajagbe, Ilorin Fọfọ ni gbọngan aṣa ati iṣe-ọna, Kwara State Arts Council, to wa ni…