Eyi ni bi wọn ṣe yinbọn pa Ẹbila, ọga awọn ‘One Million Boys’ n’Ibadan

Ọlawale Ajao, Ibadan Lẹyin oṣu mẹta ti awọn ikọ ọmọ iṣọta ta a mọ si ‘One Million…

Kẹhinde ja purofẹsọ lole, o tun fipa ba agbalagba lo pọ

Oluyinka Soyemi, Ado-Ekiti Iwa ọdaju ti ọkunrin kan, Kẹhinde Oke, hu loṣu kejila, ọdun to kọja,…

Awọn ọmọ ẹgbẹ PDP binu si Agboọla, Igbakeji Gomina Ondo

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Ọpọlọpọ awọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu PDP nipinlẹ Ondo ni wọn fẹhonu han tako…

2023: Ilẹ Yoruba ṣetan lati gbajọba, ọrọ ku sọwọ Tinubu, Fayẹmi – ARG

Oluyinka Soyemi, Ado-Ekiti Ẹgbẹ Afẹnifẹre Renewal Group (ARG) ti sọ pe ilẹ Yoruba ṣetan lati gba…

Magu, olori EFCC tẹlẹ, ti tun n kawọ sẹyin rojọ

Loni-in ọjọ Aje, Mọnde, ọjọ kẹtala oṣu keje, ọdun 2020, Ọgbẹni Ibrahim Magu ti i ṣe…

Eeyan marundinlaaadọrin ko arun Korona lọjọ kan ṣoṣo nipinlẹ Ọyọ

Ọlawale Ajao, Ibadan Lọjọ Abamẹta, Satide to kọja, nikan ṣoṣo, eeyan marundinlaaadọrin (65) lo ko arun Korona…

Awọn oluranlọwọ igbakeji gomina Kwara ti ko arun Korona

Stephen Ajagbe, Ilọrin Lẹyin ọjọ diẹ ti arun Korona pa olori oṣiṣẹ gomina nipinlẹ Kwara, Aminu Adisa…

Lẹyin ọjọ mẹrin to dawati, ileeṣẹ panapana ri oku Abdullateef ninu odo n’Ilọrin

Stephen Ajagbe, Ilọrin Lẹyin ọjọ mẹrin ti wọn ti n wa Abdulwaheed Abdullateef, ẹni ọdun mẹrindinlọgbọn,…

Ọbaladi Afọn tun waja, lọjọ keji ti Olu Imaṣayi papoda

Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Ọbaladi ti Afọn, nijọba ibilẹ Imẹkọ-Afọn, nipinlẹ Ogun, Ọba Busari Adetọna, naa ti…

Lẹyin ọsẹ mẹta ti Ajimọbi ku ni kọmiṣanna rẹ ku sinu ijamba mọto

Ọlawale Ajao, Ibadan Lẹyin ọsẹ mẹta ti gomina ipinlẹ Ọyọ tẹlẹ, Sẹnetọ Abiọla Ajimọbi ku, ọkan…

Ko sẹni to yọ orukọ mi kuro ninu awọn oludije – Akeredolu

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu, ti ni ko si ootọ ninu ahesọ to n…