Ẹ woju Wolii Festus to fẹẹ fọmọ wolii ẹgbẹ ẹ ṣoogun l’Ondo

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Awọn ọlọpaa ni iwadii ṣi n tẹsiwaju lori ọrọ ọmọbinrin kan ti ọrẹkunrin…

Ẹ woju awọn ọdaran tọwọ tẹ l’Ekoo, oku ọrun lawọn maa n ja lole owo nla

Adefunkẹ Adebiyi Awọn ti ẹ n wo fọto wọn yii, Osita Nwafor, Nwogu Joseph, Anthony Odama,…

Nnkan de! Sunday ti wọn mu pe o n pa awọn eeyan l’Akinyẹle ti sa lọ lagọọ ọlọpaa n’Ibadan

Ọlawale Ajao, Ibadan Iroyin ibanujẹ gbaa lo jẹ fawọn olugbe ijọba ibilẹ Akinyẹle, awọn olugbe Ibadan…

Ṣe asasi waa leleyii ni abi eedi, Pele Onikoko si pokunso sinu ṣọọbu rẹ niluu Gbọngan

Florence Babaṣọla, Oṣogbo Ko sẹni ti ko mọ Pele Onikoko niluu Gbọngan nipinlẹ Ọṣun, yatọ si…

Korona ti tun pa ẹni kan l’Ekiti, bẹẹ lawọn to lugbadi ẹ ti kọja igba

Oluyinka Soyemi, Ado-Ekiti Ipinlẹ Ekiti ti padanu ẹni kẹta sọwọ arun Koronafairọọsi pẹlu bi awọn to…

Gbajumọ oṣere, Ọmọtọla Jalade, ti ko Koro o

Faith Adebola Gbajumọ oṣere ori itage nni, Ọmọtọla Jalade-Ekeinde, ti ko arun Korona to wa nita…

Sanni Abacha ti tun fi biliọnu meji ataabọ naira ranṣẹ sawọn ọmọ Naijiria ‘lati ọrun’

Lati ọjọ kẹjọ, oṣu kẹfa, ọdun 1998, ti Ọgagun Sanni Abacha to ti figba kan jẹ…

Emi kọ ni mo pa iyawo atawọn ọmọ mi o – Oyediran (Fidio)

Ipari oṣu to kọja ni iroyin naa gbalẹ pe nọọsi kan, Solomon Tunde Oyediran, gun iyawo,…

Oloṣelu Eko, Lanre Razak, ti ku o!

Ọjọ Abamẹta, Satide, ọjọ kẹẹẹdogun, oṣu yii, ni agba oloṣelu ilu Ẹpẹ, nipinlẹ Eko, to ti…

O yẹ ki Aarẹ Buhari ko awọn igbimọ alaṣẹ rẹ wa ka jọ waa bẹ Yeye Ọṣun lori arun Korona ni- Ọṣunbiyii

Florence Babaṣọla, Oṣogbo Lati igba ti ayẹyẹ ọdun Ọṣun Oṣogbo to waye lopin ọsẹ to kọja…

Itajẹsilẹ to n ṣẹlẹ lojoojumọ le fa ibinu Ọlọrun fun Naijiria-Ẹlẹbuibọn

Florence Babaṣọla, Oṣogbo Araba Awo ti ilu Oṣogbo, Oloye Ifayẹmi Ẹlẹbuibọn, ti ke sijọba apapọ orileede…