O ma ṣe o, o ku oṣu meji pere ki ọmọbinrin yii ṣeyawo ni mọto pa a lori ọkada

Faith Adebọla Ibanujẹ ti dori agba kodo fawọn mọlẹbi ọmọbinrin arẹwa ti ẹ n wo fotọ…

Awọn adigunjale to yinbọn pa oṣiṣẹ ileepo Akurẹ d’ero ile-ẹjọ

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Meji ninu awọn adigunjale to yinbọn pa oṣiṣẹ ileepo kan lọjọ kẹtalelogun oṣu…

Ẹ wo Bọọda Tiṣa, o ti rẹwọn he o, ọmọ ọdun mẹwaa lo fipa ba sun l’Akurẹ

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Tiṣa kan ti wọn porukọ rẹ ni Ọmọtayọ Adanlawọ ti gba idajọ ẹwọn…

Adeṣọla Ọlaniyan gbade, o di ọba ilu Ipokia tuntun

Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Ọjọbọ, Wẹsidee, ọsẹ yii, ni Gomina ipinlẹ Ogun, Ọmọọba Dapọ Abiọdun, fun Onipokia…

Ẹ je ka bẹ Pasitọ Adeboye atawọn olori ẹlẹsin to ku, ki wọn ma ba aṣa Yoruba jẹ o

Ọjọgbọn agbaye kan, Purofẹsọ Toyin Falọla, ti sọ pe gbogbo ẹni yoowu to ba fẹran aṣa…

Adajọ ti gba beeli awakọ to pa Tolulọpẹ Arotile

Lẹyin ti ile-ẹjọ gba beeli ọmọkunrin to wa mọto, ati ẹni to ni mọto to pa…

Baba ọgọrin ọdun to fipa ba ọmọ ọdun marun-un lo pọ l’Agege loun fẹẹ fẹ ẹ ni

 Faith Adebọla Tika-tẹgbin lawọn eeyan n wo baba ẹni ọgọrin ọdun kan, Ebenezer Ọlaiya Oyewọle, nigba…

Adedeji, ayederu lọọya, n lọ sẹwọn ọdun mẹta ba a ṣe kọwe rẹ l’Abẹokuta

Adefunkẹ Adebiyi,Abẹokuta  Kootu ko fi ẹjọ ayederu lọọya kan, Adedeji Ebenezer, ẹni ti aṣiri ẹ tu…

Ewu nla ni eto Big Brother fun ọjọ iwaju awọn ọdọ wa – Ọọni Ogunwusi

Arole Oduduwa, Ọọni Adeyẹye Ẹnitan Ogunwusi ti kọminu lori iha ti awọn ọdọ orileede Naijiria kọ…

Oju ole ree: Lati ipinlẹ Anambra ni Chidi ati Obinna ti wa n ja ọkada gba l’Owode Yewa

Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Lẹyin ti wọn ti wa si Owode Yewa lẹẹmẹta, ti wọn si ti…

Ẹ gba mi o: awọn ọlopaa SARS ti ọmọ mi mọle nitori owo biribiri ti wọn fẹẹ gba ti ko fun wọn

Ile-ẹjọ giga Eko lo pariwo lọ o. Obinrin oniṣowo Eko kan, Regina Stanley ni. O pariwo…