Ọga ọlọpaa patapata nilẹ wa, Muhammed Adamu, ti gbẹsẹ le ẹka ileesẹ ọlọpaa ti wọn gbe kalẹ lati maa gbogun ti idigunjale ti wọn n pe ni SARS kaakiri gbogbo ipinlẹ to wa ni Naijiria. O ni eegun wọn ko gbọdọ ṣẹ mọ. Ninu atẹjade to fi sita llọjọ Aiku, Sannde, ọsẹ yii lo ti kede ọrọ yii.
Check Also
Nitori to ni oun yoo fopin si eto aabo ni Borno ati Yobe, PDP Ekiti sọrọ si Fayẹmi
Taofeek Surdiq, Ado-Ekiti Ẹgbẹ PDPipinlẹ Ekiti ti yẹgẹ ẹnu si gomina ipinlẹ Ekiti, Dokita Kayọde …
2 comments
Leave a Reply
You must be logged in to post a comment.
Well . Odara be . Sugbon ejekaro nu jinle nitori awon ajinigbe . Awon ole . Ki ijoba bawase agbekale . Todara lori atunse awon kidnapper ati awon ole pelu awo omo cut tiwongba ode kan ti. Afiki awon ijoba na bawawa nkanse si
O dara