“Ẹ MA JẸ KAWỌN ỌMỌLEEWE WỌLE O, Ẹ JẸ KO D’ỌDUN TO N BỌ”

Ẹgbẹ awon olukọ ni yunifasiti gbogbo nilẹ yii ti wọn n pe ni ASUU ti sọ…

Aṣiṣe nla ni bi mo ṣe fi Agbọọla ṣe igbakeji mi – Akeredolu

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ. Asiṣe nla gbaa lo jẹ fun mi lori bi mo ṣe yan Agboọla…

Kọmiṣanna eto ẹkọ ti ko si nipinlẹ Ogun n fa wa sẹyin-Ẹgbẹ Akẹkọọ

Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta  Apapọ ẹgbẹ akẹkọọ nipinlẹ Ogun, ‘National Association of Ogun State Students’ (NAOSS), ti fi…

Korona: Ijọba ko aadọta eeyan nile-ijo taka-sufee n’Ilọrin

Stephen Ajagbe, Ilorin Fun pe wọn tapa sofin to de ṣiṣi ile-ijo lasiko ajakalẹ arun Korona,…

Haa, awọn ajinigbe ti gbe’yawo atọmọ olori ile-igbimọ aṣofin ipinlẹ Edo tẹlẹ lọ o

Ajalu ti di meji fun wọn ni ipinle Edo bayii o. Wọn ti ji iyawo ati…

Lẹyin ti Ojo atawọn ọrẹ ẹ fipa ba ọmọ lo pọ tan ni wọn tun fẹẹ ki iya mọlẹ n’Ikarẹ-Akoko

  Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ.    Awọn afurasi mẹrin ti wọn fẹsun ifipabanilopọ kan ni wọn ti…

Ojoojumọ lọkọ mi maa n lu mi nilukilu nitori ibalopọ, mi o fẹ ẹ mọ – Esther

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ  Kootu kọkọ-kọkọ to wa lagbegbe Oke-Ẹda, l’Akurẹ, ni obinrin ẹni ọdun marundinlogoji kan, Esther…

Awọn oṣiṣẹ ijọba Ekiti fẹẹ ba Fayẹmi k’ẹsẹ bọ ṣokoto ija o

Gbogbo ẹgbẹ awọn oṣịṣẹ patapata ti para pọ ni ipinlẹ Ekiti bayii o, wọn si ni…

O ga o: terela Dangote tun g’ori ọlọkada l’Agọ-Iwoye, o pa a patapata

Laaarọ yii ni. Ere buruku ni wọn ni mọto terela Dangote naa n ba bọ, o…

O ṣẹlẹ! Akeredolu sọrẹnda

  Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ   Lẹyin bii ọdun mẹta o le to ti gori aleefa, Gomina…

‘Nitori owo ni mo ṣe bẹ ọrẹ mi lori o!’, Moses lo sọ bẹẹ

Afi ki eeyan maa ṣọra ko too finu han fẹni kan. Awọn ọrẹ a maa ṣeku…