Ẹgbẹ awon olukọ ni yunifasiti gbogbo nilẹ yii ti wọn n pe ni ASUU ti sọ…
Aṣiṣe nla ni bi mo ṣe fi Agbọọla ṣe igbakeji mi – Akeredolu
Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ. Asiṣe nla gbaa lo jẹ fun mi lori bi mo ṣe yan Agboọla…
Kọmiṣanna eto ẹkọ ti ko si nipinlẹ Ogun n fa wa sẹyin-Ẹgbẹ Akẹkọọ
Adefunkẹ Adebiyi, Abẹokuta Apapọ ẹgbẹ akẹkọọ nipinlẹ Ogun, ‘National Association of Ogun State Students’ (NAOSS), ti fi…
Korona: Ijọba ko aadọta eeyan nile-ijo taka-sufee n’Ilọrin
Stephen Ajagbe, Ilorin Fun pe wọn tapa sofin to de ṣiṣi ile-ijo lasiko ajakalẹ arun Korona,…
Haa, awọn ajinigbe ti gbe’yawo atọmọ olori ile-igbimọ aṣofin ipinlẹ Edo tẹlẹ lọ o
Ajalu ti di meji fun wọn ni ipinle Edo bayii o. Wọn ti ji iyawo ati…
Lẹyin ti Ojo atawọn ọrẹ ẹ fipa ba ọmọ lo pọ tan ni wọn tun fẹẹ ki iya mọlẹ n’Ikarẹ-Akoko
Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ. Awọn afurasi mẹrin ti wọn fẹsun ifipabanilopọ kan ni wọn ti…
Ojoojumọ lọkọ mi maa n lu mi nilukilu nitori ibalopọ, mi o fẹ ẹ mọ – Esther
Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Kootu kọkọ-kọkọ to wa lagbegbe Oke-Ẹda, l’Akurẹ, ni obinrin ẹni ọdun marundinlogoji kan, Esther…
Awọn oṣiṣẹ ijọba Ekiti fẹẹ ba Fayẹmi k’ẹsẹ bọ ṣokoto ija o
Gbogbo ẹgbẹ awọn oṣịṣẹ patapata ti para pọ ni ipinlẹ Ekiti bayii o, wọn si ni…
O ga o: terela Dangote tun g’ori ọlọkada l’Agọ-Iwoye, o pa a patapata
Laaarọ yii ni. Ere buruku ni wọn ni mọto terela Dangote naa n ba bọ, o…
O ṣẹlẹ! Akeredolu sọrẹnda
Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Lẹyin bii ọdun mẹta o le to ti gori aleefa, Gomina…
‘Nitori owo ni mo ṣe bẹ ọrẹ mi lori o!’, Moses lo sọ bẹẹ
Afi ki eeyan maa ṣọra ko too finu han fẹni kan. Awọn ọrẹ a maa ṣeku…