Ajalu buruku! Igbakeji kọmiṣanna ọlọpaa Eko pokunso

 

Adewale Adeoye

Titi di asiko ta a n koroyin yii j lw lọrọ iku igbakeji Kọmianna lpaa nipinl Eko, Oloogbe D.C.P Gbolahan Oyedemi, to pokunso sinu il r niluu Ogbomọṣọ, nipinlẹ Ọyọ, lj Aje, Mọnde, j kinin-ni, oKẹrin, dun 2024 yii i n ya gbogbo eeyan lenu gidigidi pe ki lo Le Mu ọkunrin naa pa ara ẹ.

ALAROYE gbọ pe olude Ajinde ni ọkunrin naa lọọ ṣe ni ilú abinibi rẹ l’Ogbomọṣọ.

Wọn ni bi okunrin ti wọn ni ko niyawo, òun nìkan lo n da gbe yii ṣe delẹ lo ni ki onikaluku awọn ẹṣọ to n sọ ọ maa lọ sile, ki onikaluku lọọ ṣọdun nile wọn.

Leyin tawọn ọmọọṣẹ rẹ lọ tan ni wọn ni ọkunrin to ti figba kan j ẹṣọ (ADC) fun gomina ipinle y tlOloogbe Christopher Adebay Alao Akala nigba aye rẹ pojobo okun, to sí so ara rẹ, nibi ti ọlọjọ de ba a.

Agbọ-sọgba-nu ni iku igbakeji kọmiṣanna ọlọpaa Eko ọhun si gbogbo awọn to gbọ ọ.

Iwadii akoroyin wa fi han pe Oyedemi ati iya rẹ ni wọn jọ n gbe ile to kọkọ kọ fún iya rẹ, eyi to wa ni agbègbè Randa, niluu Ogbomoso, ko too ṣẹṣẹ kọ omi-in, nibi ti òun nìkan n gbe, to sí pada pokunso si bayii.

kan lara awọn r oloogbe naa toun ati  jọọ iṣẹ pap ld gomina ipinl y tl sọ pe:

Ile nla kan bayii to k fun iya r loun ati mama rẹ j n gbe tl lagbegbe kan ti wn n pe ni Randa, niluu Ogbomọṣọ, ugbn loju-s to pari ile tuntun miin to kọ funra lo ko l sile hun to wa lagbegbe Petros Academy, ni Federal Low-cost. Inu ile hun lawọn araadugbo naa ti ba oku r laaar kutukutu jọ Iṣẹgun, Tusidee, j keji, oKẹrin, dun yii.

Ọga olopaa kan to ba akoroyin Daily Trust sọrọ sọ pe awọn ti bẹrẹ iwadii, ati pe gbogbo awọn omoose rẹ, to fi mọ awọn to ri i gbeyin ko too pokunso ni wọn máa f’oro wa l’enu wo

 

 

Leave a Reply