O ma ṣe o, Oloye Ayọ Fasanmi ti ku o

Florence Babaṣọla, Oṣogbo Ọkan pataki ninu awọn aṣaaju Yoruba, to tunjẹ ọkan ninu awọn olori ẹgbẹ…

Nitori bi wọn ko ṣe fun un ni tikẹẹti ni PDP, Agboola Ajayi fẹẹ dara pọ mọ ẹgbẹ ZLP

Igbakeji Gomina ipinlẹ Ondo, Agbọọla Ajayi, ti ko ọrọ rẹ to sọ lọsẹ to kọja pe…

O ma ṣe o, wọn ni Ọlabọde luyawo ẹ pa toyuntoyun l’Akurẹ

Awọn ọlọpaa ti mu ọkunrin kan ti wọn n pe ni Oluwaṣeun Ọlabọde o. Ẹsun pe…

‘Ẹ ma waa ki mi nile lọjọ ọdun o!’, Buhari ṣekilọ

Aarẹ Muhammadu Buhari ti ṣekilọ pe ki awọn eeyan ma waa ki oun nile lọjọ ọdun…

Wọn dana sun awọn adigunjale ti wọn fọ banki l’Okeho, ti wọn tun pa ọlọpaa kan

Nnkan ko ṣenuure fun aọn adigunjale kan ti awọn araalu dana sun ni Ọjọruu, Wẹsidee, ọsẹ…

Ijọba yoo ṣi awọn ileejọsin loṣu to n bọ nipinlẹ Ogun– Dapọ Abiọdun

Adefunkẹ Adebiyi, Ogun Ọjọruu, Wẹsidee, ọsẹ yii, ni Gomina ipinlẹ Ogun, Omọọba Dapọ Abiọdun, kede lọfiisi…

O ma ṣe o,  awọn janduku pa eeyan mẹtala ninu mọlẹbi kan naa ni Kogi

 Eeyan mẹrinla lawọn janduku kan pa loru Ọjọruu, Wẹsidee, ọsẹ yii, nipinlẹ Kogi, nigba ti awọn…

Eyi le o, lọjọ kan ṣoṣo, Korona paayan mẹta l’Ọyọọ

Ọlawale Ajao, Ibadan Gende Ọlọrun mẹta lajakalẹ arun Korona pa lọjọ Iṣẹgun, Tusidee, ọsẹ yii. O…

Ayedatiwa ni yoo ṣe igbakeji Gomina Akeredolu ninu eto idibo ti yoo waye loṣu kẹwaa

Oluṣẹyẹ Iyiade, Akurẹ Gomina ipinlẹ Ondo, Rotimi Akeredolu  ti forukọ ẹni to fẹẹ fi ṣe igbakeji…

Haa, obinrin yii si n gba iṣo mọ ọmọ ọkọ ẹ kekere yii lori

Awọn ọlọpaa Ṣagamu ti mu un o. Abimbọla. Koda wọn tun mu ọkọ ẹ naa, Taiwo…

Pasito Kumuyi, olori ijọ Deeper Life, kọ Bibeli tuntun

Olori ati Oludasilẹ ijọ awọn Dipa (Deeper Life) Pasitọ William Kumuyi, ti kọ Bibeli tuntun ni…